ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.
Àwọn márùn-ún ló ti wà ní agodo àwọn àwọn ọlọ́pàá báyìí lórí ẹ̀sùn pé wọ́n ta ọmọ ìkókó, ọmọ ọ̀sẹ̀ ...
Àwọn márùn-ún ló ti wà ní agodo àwọn àwọn ọlọ́pàá báyìí lórí ẹ̀sùn pé wọ́n ta ọmọ ìkókó, ọmọ ọ̀sẹ̀ ...
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú NNPP méjì tí wọ́n jẹ́ ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣojúṣòfin ló ti digbádagbọ̀n wọn kúrò nínú ẹgbẹ́ ...
Ilé ẹjọ́ gíga ìpínlẹ̀ Èkìtì ti dájọ́ ikú fún David Isaiah fún ẹ̀sùn ìpànìyàn. Ẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ni David, ẹ̀sùn ...
Abdullai Ganduje; ẹni tó jẹ́ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC sọ̀rọ̀ níbi ìgbaniwọlé Gómìnà ìpínlẹ̀ Delta àti àwọn ẹmẹ̀wàá rẹ̀ tó ...
Ọwọ́ àwọn ọlọ́pàá ti tẹ àwọn mẹ́jọ kan tí wọ́n pa ọmọ ọdún mẹ́fà kan nípakúpa. Abúlé Bura-Bunga ní agbègbè ...
Gómìnà ìpínlẹ̀ Gombe; Muhamadu Inuwa Yahaya ti ṣe ìlérí mílíọ̀nù méjì náírà fún ọ̀kọ̀ọ̀kan ẹbí àwọn èèyàn tí ọkọ̀ tẹ̀ ...
Gọ́mìnà ìpínlẹ̀ Delta; Sheriff Oborevwori ti kéde ìṣípòpadà rẹ̀ láti jíjẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú PDP sí ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú APC. ...
Ilé alájà méjì kan tó wà ní òpópónà ọ̀rẹ́mẹ́ta ní Ojodu-Berger, Èkó ti dà wó ní àárọ̀ òní ọjọ́ Àbámẹ́ta, ...
Ilé ẹjọ́ tó fìkàlẹ̀ sí ìpínlẹ̀ Ekiti ti pàṣẹ kí Joy Ikoja ó lọ rọ́kún lọ́gbà ẹ̀wọ̀n lórí ẹ̀sùn pé ...
Àkọlé tó gba ojú ìwé ìròyìn kan àti ìbéèrè tí àwọn èèyàn ń bèèrè ni pé kín ni ìdí tí ...
Lorem ipsum dolor sit amet, consectetuer adipiscing elit. Aenean commodo ligula eget dolor.
SUBSCRIBE
We bring you the best Premium WordPress Themes that perfect for news, magazine, personal blog, etc. Check our landing page for details.
© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group
© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group