ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.
Ilé iṣẹ́ ológun ilẹ̀ yìí, ẹ̀ka àwọn jagunjagun ojú òfurufú ti kéde pé àwọn ti pa ọlọ́wọ́ ọ̀tún Bello Turji ...
Ilé iṣẹ́ ológun ilẹ̀ yìí, ẹ̀ka àwọn jagunjagun ojú òfurufú ti kéde pé àwọn ti pa ọlọ́wọ́ ọ̀tún Bello Turji ...
Àwọn márùn-ún ló ti wà ní agodo àwọn àwọn ọlọ́pàá báyìí lórí ẹ̀sùn pé wọ́n ta ọmọ ìkókó, ọmọ ọ̀sẹ̀ ...
Níbi ibùdó àwọn ọlọ́pàá tó wà ní Isuofia ní ìjọba ìbílẹ̀ Aguata ni ìkọlù náà ti wáyé. Alẹ́ àná Ọjọ́bọ, ...
Àwọn ọmọ ẹgbẹ́ òṣèlú NNPP méjì tí wọ́n jẹ́ ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣojúṣòfin ló ti digbádagbọ̀n wọn kúrò nínú ẹgbẹ́ ...
Ilé ìwé gíga Babcock tó wà ní Ilishan ti fèsì sí ọ̀rọ̀ Oladipupo Sijuola ọmọ arábìnrin Fijabi Omotayo tó pòórá ...
Ilé ẹjọ́ gíga ìpínlẹ̀ Èkìtì ti dájọ́ ikú fún David Isaiah fún ẹ̀sùn ìpànìyàn. Ẹni ọdún mẹ́rìndínlọ́gbọ̀n ni David, ẹ̀sùn ...
Ní agbègbè Ajowa Akoko ní ìpínlẹ̀ Ondo, nǹkan ò fara rọ fún arákùnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Monday ...
Natasha Akpoti-Uduaghan; ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà ilẹ̀ yìí ti kọ lẹ́tà ìtọrọ àforíjì sí olórí ilé ìgbìmọ̀ àṣòfin ilẹ̀ ...
Ọwọ́ àwọn ọlọ́pàá ti tẹ àwọn mẹ́jọ kan tí wọ́n pa ọmọ ọdún mẹ́fà kan nípakúpa. Abúlé Bura-Bunga ní agbègbè ...
Gómìnà ìpínlẹ̀ Gombe; Muhamadu Inuwa Yahaya ti ṣe ìlérí mílíọ̀nù méjì náírà fún ọ̀kọ̀ọ̀kan ẹbí àwọn èèyàn tí ọkọ̀ tẹ̀ ...
Lorem ipsum dolor sit amet, consectetuer adipiscing elit. Aenean commodo ligula eget dolor.
SUBSCRIBE
We bring you the best Premium WordPress Themes that perfect for news, magazine, personal blog, etc. Check our landing page for details.
© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group
© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group