GBỌ̀GÁN ÌDÁNWÓ WÓ PA ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ TARABA.
Gbọ̀gán ìdánwò ilé ìwé girama ìjọba tó wà ní Namnai ní ìjọba ìbílẹ̀ Gassol ní ìpínlẹ̀ Taraba ti wó lé ...
Gbọ̀gán ìdánwò ilé ìwé girama ìjọba tó wà ní Namnai ní ìjọba ìbílẹ̀ Gassol ní ìpínlẹ̀ Taraba ti wó lé ...
Ààrẹ orílẹ̀-ède wa Nàìjíríà; Aṣíwájú Bola Ahmed Tinubu ti sọ̀rọ̀ nípa ipò tí orílẹ̀-ède Nàìjíríà wà báyìí àti àlàkalẹ̀ ọjọ́ ...
Orílẹ̀-ède Saudi ti kéde pé àwọn ti rí òṣùpá titun tó ṣe àmì ìbẹ̀rẹ̀ oṣù ọdún iléyá. Ọ̀la, ọjọ́ kejìdínlógún, ...
Ilé ẹjọ́ gíga ìjọba tó fìkàlẹ̀ sí Kaduna ti pàṣẹ kí Gómìnà ìpínlẹ̀ Kaduna tẹ́lẹ̀rí; Nasir El-Rufai àti àwọn márùn-ún ...
Gómìnà ìpínlẹ̀ Akwa Ibom; Umo Eno ti pàṣẹ fún gbogbo àwọn kọmíṣọ́nà rẹ̀ pé kí wọn ó tẹ̀lé òun kálọ ...
Ọmọ odún mẹ́rìnlá kan tí a kò ní àǹfààní àtidárúkọ rẹ̀ ti sá àsálà fún ẹ̀mí rẹ̀ kúrò nílé ọkọ ...
Hamdiyyah Sharif; ọmọbìnrin tó ké sí gómìnà ìpínlẹ̀ Sokoto pé kí ó wá nǹkan ṣe sí ọ̀rọ̀ àwọn agbésùnmọ̀mí ti ...
Gómìnà ìpínlẹ̀ Borno; Babangana Zulum ti sọ gudugbẹ ọ̀rọ̀ lónìí nínú ìfọ̀rọ̀wánilẹ́nuwò tó ṣe pẹ̀lú àwọn akọ̀ròyìn News central. Ó ...
Arákùnrin kan tí wọ́n pe orúkọ rẹ̀ ní Udochi Amala ti dáná sun ìyàwó àti ọmọ rẹ̀ nítorí pé ó ...
Àwọn kan tí wọ́n fura sí pé wọ́n jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ òkùnkùn ni wọ́n ti ṣá arákùnrin kan tí wọ́n ...
Lorem ipsum dolor sit amet, consectetuer adipiscing elit. Aenean commodo ligula eget dolor.
SUBSCRIBE
We bring you the best Premium WordPress Themes that perfect for news, magazine, personal blog, etc. Check our landing page for details.
© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group
© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group