ONÍRÒYÌN KAN DÁKẸ́ NÍBI TÓ TI Ń MÚRA ÀTI KA ÌRÒYÌN.
Ìròyìn tó gba àwọn ojú ìwé ìròyìn kan láàárọ̀ yìí ni ikú arábìnrin Agbakaizu; ẹni tó jẹ́ akàròyìn ní ilé ...
Ìròyìn tó gba àwọn ojú ìwé ìròyìn kan láàárọ̀ yìí ni ikú arábìnrin Agbakaizu; ẹni tó jẹ́ akàròyìn ní ilé ...
Ilé ìwé gíga Babcock tó wà ní Ilishan ti fèsì sí ọ̀rọ̀ Oladipupo Sijuola ọmọ arábìnrin Fijabi Omotayo tó pòórá ...
Ní agbègbè Ajowa Akoko ní ìpínlẹ̀ Ondo, nǹkan ò fara rọ fún arákùnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Monday ...
Abdullai Ganduje; ẹni tó jẹ́ alága ẹgbẹ́ òṣèlú APC sọ̀rọ̀ níbi ìgbaniwọlé Gómìnà ìpínlẹ̀ Delta àti àwọn ẹmẹ̀wàá rẹ̀ tó ...
Alága ìjọba ìbílẹ̀ Hong ní ìpínlẹ̀ Adamawa; Usman Wa’anganda bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ lórí àwọn ìkọlù tó ti wáyé ní ...
Natasha Akpoti-Uduaghan; ọmọ ilé ìgbìmọ̀ aṣòfin àgbà ilẹ̀ yìí ti kọ lẹ́tà ìtọrọ àforíjì sí olórí ilé ìgbìmọ̀ àṣòfin ilẹ̀ ...
Ọjọ́ tí àwọn èèyàn ò le gbàgbé bọ̀rọ̀ ni òní jẹ́ ní Agege látàrí ìjàmbá tó wáyé láàárọ̀ yìí. Ọkọ̀ ...
Ìjà burúkú kan bẹ́ sílẹ̀ láàrin Olamide àti ìyàwó rẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ogun, irin tó gbé sókè pé kó fi ...
Ọjọ́ àìkú, ọjọ́ kọkànlélógún tó kọjá yìí ni àwọn agbébọn mẹ́wàá ṣàdédé ya wọ ibùdókọ̀ Ilesa Baruba tó wà ní ...
Grace Walter; ẹni ọdún márùndínlọ́gọ́ta àti ọmọ rẹ̀; Blessing Walter; ẹni ogún ọdún gbìmọ̀pọ̀ ta ọmọ tí Blessing bí ní ...
Lorem ipsum dolor sit amet, consectetuer adipiscing elit. Aenean commodo ligula eget dolor.
SUBSCRIBE
We bring you the best Premium WordPress Themes that perfect for news, magazine, personal blog, etc. Check our landing page for details.
© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group
© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group