• About
  • Advertise
  • Careers
  • Contact
Tuesday, May 13, 2025
  • Login
  • Register
No Result
View All Result
NEWSLETTER
ÌWÉ ÌRÒYÌN YORÙBÁ
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • All
    • ijamba oko
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọ̀rọ̀ ìdílé
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
    Àmì ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Nàìjíría

    ỌWỌ́ TẸ ONÍLÉ ÌTURA TÓ Ń PA ÀWỌN ARÌRÌNÀJÒ.

    ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU KÉDE ÌPÍNLẸ̀ RIVERS NÍ ÌPÍNLẸ̀ PÀJÁWÌRÌ.

    KO PỌN DANDAN FÚN MI LÁTI PADÀ SÍPÒ GÓMÌNÀ – SIMINALAYI FUBARA.

    ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ MẸ́TA LÓ JẸ́RÌÍ TAKO TIMILEHIN AJAYI NÍLÉ ẸJỌ́.

    ILÉ ẸJỌ́ YỌ̀ǸDA ÌYÓKÙ HAFSOH FÚN ÀWỌN ÒBÍ RẸ̀.

    WỌ́N TI ṢÁ ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́JÁDE MÉJÌ PA.

    WỌ́N TI ṢÁ ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́JÁDE MÉJÌ PA.

    ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN MÉJÌ GBÉNÁ WOJÚ ARA WỌN NÍ ÌPÍNLẸ̀ RIVERS.

    KÒ SÍ ÀÀYÈ FÚN ÀWỌN ADÁHUNṢE NÍLẸ̀ WA MỌ́ – ÀWỌN ARÁ ÌPÍNLẸ̀ RIVERS.

    ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU YÓÒ ṢE ÌWÚRE ỌJỌ́ ÌBÍ RẸ̀ LÓNÌÍ.

    ẸGBẸ̀RIN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ NI A TI PA LÁBẸ́ ÌṢEJỌBA BOLA AHMED TINUBU – MÍNÍSÍTÀ FÚN ÈTÒ ÀÀBÒ.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    A Ó FI ÒFIN GBÉ OLADIPUPO – ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    ÀWỌN ÒBÍ TOPE LÙ Ú PA NÍ ÒǸDÓ.

    ÀWỌN ÒBÍ TOPE LÙ Ú PA NÍ ÒǸDÓ.

    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • All
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    ỌKÙNRIN MỌ́KÀNLÉLÓGÚN LÓ BÁ ÌYÀWÓ MI LÒ PỌ̀- ÌJỌBA LANDE

    MI Ò NÍ LE BÁ BABA TEE ṢIṢẸ́ PỌ̀ – ÌJỌBA LANDE.

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    Ramadan Kareem!

    Ramadan Kareem!

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • All
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
    • Oge Ṣiṣe
    ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU KÉDE ÌPÍNLẸ̀ RIVERS NÍ ÌPÍNLẸ̀ PÀJÁWÌRÌ.

    KO PỌN DANDAN FÚN MI LÁTI PADÀ SÍPÒ GÓMÌNÀ – SIMINALAYI FUBARA.

    ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ MẸ́TA LÓ JẸ́RÌÍ TAKO TIMILEHIN AJAYI NÍLÉ ẸJỌ́.

    ILÉ ẸJỌ́ YỌ̀ǸDA ÌYÓKÙ HAFSOH FÚN ÀWỌN ÒBÍ RẸ̀.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    A Ó FI ÒFIN GBÉ OLADIPUPO – ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN AWAKỌ̀ BRT TÓ PA BAMISHE.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN AWAKỌ̀ BRT TÓ PA BAMISHE.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ PA ÀWỌN ÈÈYÀN TÓ LỌ SÌNKÚ ÀWỌN TÍ WỌ́N TI PA TẸ́LẸ̀.

    ARABÌNRIN KEMI KÚ TOYÚNTOYÚN NÍTORÍ KÒ NÍ ẸGBẸ̀RÚN LỌ́NÀ Ẹ̀Ẹ́DẸ́GBẸ̀TA NÁÍRÀ.

    NATASHA TỌRỌ ÀFORÍJÌ Ẹ̀DẸ LỌ́WỌ́ AKPABIO LÓRÍ Ẹ̀SÙN TÓ FI KÀN ÁN.

    ỌKỌ̀ ÀJÀGBÉ ELÉJÒ JÁBỌ́ LÓRÍ AFÁRÁ PEN CINEMA.

    ỌKỌ̀ ÀJÀGBÉ ELÉJÒ JÁBỌ́ LÓRÍ AFÁRÁ PEN CINEMA.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ỌWỌ́ ÀWỌN AGBÓFINRÓ TẸ ÀWỌN TÓ PA BULAMA NÍ GOMBE.

    Trending Tags

    • Golden Globes
    • Mr. Robot
    • MotoGP 2017
    • Climate Change
    • Flat Earth
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • All
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÌPÍNLẸ̀ KWARA.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ALÁÀFIN YAN OSUNTOLA NÍ OLÙBÁDÁMỌ̀RÀN PÀTÀKÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    Ewì

    Ewì.

    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • All
    • ijamba oko
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọ̀rọ̀ ìdílé
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
    Àmì ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Nàìjíría

    ỌWỌ́ TẸ ONÍLÉ ÌTURA TÓ Ń PA ÀWỌN ARÌRÌNÀJÒ.

    ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU KÉDE ÌPÍNLẸ̀ RIVERS NÍ ÌPÍNLẸ̀ PÀJÁWÌRÌ.

    KO PỌN DANDAN FÚN MI LÁTI PADÀ SÍPÒ GÓMÌNÀ – SIMINALAYI FUBARA.

    ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ MẸ́TA LÓ JẸ́RÌÍ TAKO TIMILEHIN AJAYI NÍLÉ ẸJỌ́.

    ILÉ ẸJỌ́ YỌ̀ǸDA ÌYÓKÙ HAFSOH FÚN ÀWỌN ÒBÍ RẸ̀.

    WỌ́N TI ṢÁ ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́JÁDE MÉJÌ PA.

    WỌ́N TI ṢÁ ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́JÁDE MÉJÌ PA.

    ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN MÉJÌ GBÉNÁ WOJÚ ARA WỌN NÍ ÌPÍNLẸ̀ RIVERS.

    KÒ SÍ ÀÀYÈ FÚN ÀWỌN ADÁHUNṢE NÍLẸ̀ WA MỌ́ – ÀWỌN ARÁ ÌPÍNLẸ̀ RIVERS.

    ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU YÓÒ ṢE ÌWÚRE ỌJỌ́ ÌBÍ RẸ̀ LÓNÌÍ.

    ẸGBẸ̀RIN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ NI A TI PA LÁBẸ́ ÌṢEJỌBA BOLA AHMED TINUBU – MÍNÍSÍTÀ FÚN ÈTÒ ÀÀBÒ.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    A Ó FI ÒFIN GBÉ OLADIPUPO – ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    ÀWỌN ÒBÍ TOPE LÙ Ú PA NÍ ÒǸDÓ.

    ÀWỌN ÒBÍ TOPE LÙ Ú PA NÍ ÒǸDÓ.

    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • All
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    ỌKÙNRIN MỌ́KÀNLÉLÓGÚN LÓ BÁ ÌYÀWÓ MI LÒ PỌ̀- ÌJỌBA LANDE

    MI Ò NÍ LE BÁ BABA TEE ṢIṢẸ́ PỌ̀ – ÌJỌBA LANDE.

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    Ramadan Kareem!

    Ramadan Kareem!

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • All
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
    • Oge Ṣiṣe
    ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU KÉDE ÌPÍNLẸ̀ RIVERS NÍ ÌPÍNLẸ̀ PÀJÁWÌRÌ.

    KO PỌN DANDAN FÚN MI LÁTI PADÀ SÍPÒ GÓMÌNÀ – SIMINALAYI FUBARA.

    ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ MẸ́TA LÓ JẸ́RÌÍ TAKO TIMILEHIN AJAYI NÍLÉ ẸJỌ́.

    ILÉ ẸJỌ́ YỌ̀ǸDA ÌYÓKÙ HAFSOH FÚN ÀWỌN ÒBÍ RẸ̀.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    A Ó FI ÒFIN GBÉ OLADIPUPO – ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN AWAKỌ̀ BRT TÓ PA BAMISHE.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN AWAKỌ̀ BRT TÓ PA BAMISHE.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ PA ÀWỌN ÈÈYÀN TÓ LỌ SÌNKÚ ÀWỌN TÍ WỌ́N TI PA TẸ́LẸ̀.

    ARABÌNRIN KEMI KÚ TOYÚNTOYÚN NÍTORÍ KÒ NÍ ẸGBẸ̀RÚN LỌ́NÀ Ẹ̀Ẹ́DẸ́GBẸ̀TA NÁÍRÀ.

    NATASHA TỌRỌ ÀFORÍJÌ Ẹ̀DẸ LỌ́WỌ́ AKPABIO LÓRÍ Ẹ̀SÙN TÓ FI KÀN ÁN.

    ỌKỌ̀ ÀJÀGBÉ ELÉJÒ JÁBỌ́ LÓRÍ AFÁRÁ PEN CINEMA.

    ỌKỌ̀ ÀJÀGBÉ ELÉJÒ JÁBỌ́ LÓRÍ AFÁRÁ PEN CINEMA.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ỌWỌ́ ÀWỌN AGBÓFINRÓ TẸ ÀWỌN TÓ PA BULAMA NÍ GOMBE.

    Trending Tags

    • Golden Globes
    • Mr. Robot
    • MotoGP 2017
    • Climate Change
    • Flat Earth
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • All
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÌPÍNLẸ̀ KWARA.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ALÁÀFIN YAN OSUNTOLA NÍ OLÙBÁDÁMỌ̀RÀN PÀTÀKÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    Ewì

    Ewì.

    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú
No Result
View All Result
ÌWÉ ÌRÒYÌN YORÙBÁ
No Result
View All Result
Home Ìròyìn Ìròyìn Agbègbè

ỌWỌ́ TẸ ONÍLÉ ÌTURA TÓ Ń PA ÀWỌN ARÌRÌNÀJÒ.

Odidi yàrá kan ló sin àwọn tó ti pa sí.

by Adeola Olanrewaju
May 13, 2025
in Ìròyìn Agbègbè
0
Àmì ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Nàìjíría
0
SHARES
0
VIEWS
Pín Lórí FacebookPín Lórí ThreadsPín Lórí TwitterPín Lórí Bluesky

Láti ọdún 2024 ni Onoriode Bethel ti sọ̀nu tí wọ́n sì ti ń wá a, inú ilé ìtura Century Home tó wà ní Owehlogho ni wọ́n ti rí òkú rẹ̀ níbi tí wọ́n sin ín sí.
Ọ̀tọ̀ ni ẹni tí àwọn ọlọ́pàá wá lọ sí ilé ìtura náà tí wọ́n fi túlé kan òkú Bethel. Arákùnrin arìnrìnàjò kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Sunday Ogofohta ni ó sun ilé ìtura Century Home tí kò sì padà jáde mọ́.
Sunday ni àwọn ọlọ́pàá tọpinpin lọ sí ibẹ̀ tí wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ sí ní tú gbogbo yàrá, wọ́n kan yàrá kan tó ṣe pé òkú àwọn èèyàn ni wọ́n ń sin sínú rẹ̀, lára àwọn tó ti sin síbẹ̀ ni Bethel wà.
Iboirode ni orúkọ alámòójútó ilé ìtura yìí, ó jẹ́wọ́ pé òun ló pa Bethel ní ọdún 2024 nítorí pé ó ba òun lórúkọ jẹ́. Iṣẹ́ fi ẹ̀rọ gbowó POS ni Bethel ń ṣe, ní ọdún tó kọjá, Iboirode fi èrú gba ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá náírà lọ́wọ́ rẹ̀, nígbà tí Bethel padà ríi pé òfegèé ni àtẹ̀jíṣẹ́ owó tí Iboirode fi ránṣẹ́ sí òun, ó kò ó lójú ó sì gba owó rẹ̀.
Ẹ̀yìn ìgbà náà ni Iboirode tàn án wọ inú ilé ìtura náà pé òun fẹ́ parí ìjà náà, ó tìí wọ inụ́ yàrá náà tí ó máa ń sin àwọn èèyàn sí, ó gba píínì ẹ̀rọ POS rẹ̀ kí ó tó pa á. Lẹ́yìn náà ló wọ́ gbogbo owó tó wà nínú àpò owó náà, ó tún pe bàbá Bethel pé kí ó san owó ìtúsílẹ̀ ọmọ rẹ̀.
Ìyàwó Iboirode náà jẹ́rìí síi pé ọkọ òun máa ń pa àwọn arìnrìnàjò tó bá wá sun ilé ìtura náà, yóò wọ́ owó inú àpò owó náà yóò sì tún gba owó ìtúsílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ẹbí wọn.
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Delta wí pé afurasí náà yóò fi ojú ba ilé ẹjọ́ ní kété tí ìwádìí bá parí.

Èyí kìí ṣe ìgbà àkọ́kọ́ tí irú ìròyìn báyìí má jáde nípa àwọn tó ni ilé ìtura.
Ọdún tó kọjá náà ni wọ́n ṣe àwárí ilé ìtura Udoka Golden Point tí wọ́n tún dà pè sí La cruise níbi tí wọ́n ti ń ṣe àpatà àwọn èèyàn.
Ìròyìn náà kà báyìí pé:

Ilé ìtura ni àwọn èèyàn ń wò lórí ilẹ̀ náà, àmọ́ abattoir èèyàn ni ó wà ní ìsàlẹ̀ rẹ̀.

Udoka Golden point hotel tí wọ́n tún dà pè sí La Cruise hotel ni àsìrí rẹ̀ lu síta lónìí.

Ó lé ní ọgbọ̀n sàrê tó wà ní ìsàlẹ̀ ilé náà, ọ̀pọlọpọ̀ àwọn ohun ìjà olóró, oògùn dúdú, igbá ẹbọ àti àwọn nǹkan bẹ́ẹ̀ ló farasin sí abẹ́ ilé ìtura yìí.

Omi gbígbóná kò gbọdọ̀ pẹ́ lẹ́nu, ọwọ́ kò gbọdọ̀ pẹ́ nísà akekě, ìjọba ti da ilé náà wó.

Ojú ọ̀nà márosẹ̀ Onitsha sí Owerri ní ìpínlẹ̀ Anambra ni ilé ìtura yìí wà, àwọn ajinigbe àti agbénipa ló tẹ̀dó sí ibẹ̀ àmọ́ tí wọ́n fi ilé ìtura ni wọ́n fi bo ojú ilé náà.

Ìjọba ìpínlẹ̀ Anambra ló fúnra rẹ̀ kéde ìṣẹ̀lẹ̀ yìí lójú òpó X rẹ̀ pé àwọn da ilé ìtura là cruise wó nítorí àwọn èèyàn ni wọ́n ń pa tà ní ibẹ̀.

Mélòó la ó kà nínú eyín adìpèlé? Ṣé ẹ rántí Timothy tí wọ́n pa nílé ifẹ̀? Akẹ́kọ̀ọ́ ilé ìwé gíga Obafemi Awolowo ni Timothy, ilé ìtura Hilton ló dé sí fún ìdánwò tó fẹ́ ṣe nílé ìwé náà, oorun tí Timothy sùn nílé ìtura náà kò padà jí sáyé.
Ẹni tó ni ilé ìtura náà; Rahman Adedoyin ni adájọ́ ti dá ẹjọ́ ikú fún báyìí.

Ti àwọn onílé ìtura lápá kan, èwo ni kí èèyàn ó tún wọ akérò dáràn? Kìí tún ṣe ọkọ̀ ìgboro o, ọkọ̀ akérò ìjọba BRT ni Bamishe wọ̀ tí kò padà délé mọ́.
Ìgbẹ́jọ́ ikú Bamishe ṣẹ̀ṣẹ̀ parí ní kọ̀pẹ́kòpẹ́ yìí níbi tí adájọ́ ti pàṣẹ kí wọn ó so awakọ̀ rọ̀ títí ẹ̀mí rẹ̀ ó fi bọ́.
Ìròyìn náà kà báyìí pé
Awakọ̀ BRT tí wọ́n fi ẹ̀sùn kàn pé ó ṣekú pa Oluwabamishe Ayanwola ni ilé ẹjọ́ gíga ìpínlẹ̀ Èkó ti dá ẹjọ́ ikú fún lónìí, ọjọ́ kejì, oṣù Èbìbí.
Andrew Ominikoron ni orúkọ awakọ̀ BRT náà, ẹ̀sùn tí ìjọba fi kàn án ni pé ó bá Bamishe ní àjoṣepọ̀ tìpátìkúùkú ó sì tún gba ẹ̀mí rẹ̀.
Ẹni ọdún méjìlélógún ni Bamishe, ní ọjọ́ náà lọ́hùn-ún, Bamishe ń bọ̀ láti ibi iṣẹ́ rẹ̀ ó sì wọ ọkọ̀ BRT tí Andrew jẹ́ awakọ̀ rẹ̀. Ohùn tó fi ránṣẹ́ sí ọ̀rẹ́ rẹ̀ nípa bí Andrew ṣe gbé àwọn èèyàn kan lọ́nà àti bí ara ṣe fu ú ni ó jẹ́ ẹ̀rí nígbà tí wọ́n rí òkú rẹ̀.
Àti ìgbà náà ni ìgbẹ́jọ́ ti bẹ̀rẹ̀ tí àwọn obìnrin mìíràn tó ti fipá bá lò pọ̀ sì jáde sọ̀rọ̀.
Òní ni adájọ́ Sherifat Sonaike gbé ìdájọ́ rẹ̀ kalẹ̀ lórí ẹ̀sùn náà pé Andrew jẹ̀bi àwọn ẹ̀sùn náà ó sì pàṣẹ kí wọn ó so ó rọ̀ títí ẹ̀mí yóò fi bọ́ lára rẹ̀.

Lẹ́yìn èyi ni àwọn ẹbí Bamishe bèèrè fún ìfòfingbé àwọn tí wọ́n jọ pa á pé

Àwọn ẹbí Bamishe Ayanwola bá àwọn akọ̀ròyìn sọ̀rọ̀ lórí ìdájọ́ tí adájọ́ gbé kalẹ̀ .
Ẹ̀gbọ́n Bamishe tí orúkọ rẹ̀ jẹ́ Onaopemipo Damilola wí pé àwọn dúpẹ́ púpọ̀ lọ́wọ́ Adájọ́ Sherifat Sonaike lórí ìdájọ́ òdodo tó gbé kalẹ̀ àmọ́ àwọn tí wọ́n jọ pa Bamishe kò jẹ́jọ́ rárá.
Damilola wí pé àwọn yóò fẹ́ kí àwọn méjì tí wọ́n jọ pa ọmọ náà ó fojú ba ilé-ẹjọ́ kí wọ́n má mu un jẹ.

Facebook Comments Box
Adeola Olanrewaju

Adeola Olanrewaju

Discussion about this post

Recommended

Àwọn agbébọn

WÒLÍÌ ÌJỌ ÀGÙDÀ TÍ WỌ́N JÍ GBÉ TI GBA ÒMÌNIRA O.

2 months ago
ÀBẸ̀WÒ MI SÍ ILÉ MUHAMMADU BUHARI KÒ LỌ́WỌ́ ÒṢÈLÚ NÍNÚ – EL RUFAI

ÀBẸ̀WÒ MI SÍ ILÉ MUHAMMADU BUHARI KÒ LỌ́WỌ́ ÒṢÈLÚ NÍNÚ – EL RUFAI

1 month ago

Popular News

  • Àmì ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Nàìjíría

    ỌWỌ́ TẸ ONÍLÉ ÌTURA TÓ Ń PA ÀWỌN ARÌRÌNÀJÒ.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • KO PỌN DANDAN FÚN MI LÁTI PADÀ SÍPÒ GÓMÌNÀ – SIMINALAYI FUBARA.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • ILÉ ẸJỌ́ YỌ̀ǸDA ÌYÓKÙ HAFSOH FÚN ÀWỌN ÒBÍ RẸ̀.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • WỌ́N TI ṢÁ ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́JÁDE MÉJÌ PA.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • KÒ SÍ ÀÀYÈ FÚN ÀWỌN ADÁHUNṢE NÍLẸ̀ WA MỌ́ – ÀWỌN ARÁ ÌPÍNLẸ̀ RIVERS.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0

Connect with us

Newsletter

Lorem ipsum dolor sit amet, consectetuer adipiscing elit. Aenean commodo ligula eget dolor.
SUBSCRIBE

Category

Site Links

  • Register
  • Log in
  • Entries feed
  • Comments feed
  • WordPress.org

About Us

We bring you the best Premium WordPress Themes that perfect for news, magazine, personal blog, etc. Check our landing page for details.

  • About
  • Advertise
  • Careers
  • Contact

© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group

Welcome Back!

Sign In with Facebook
Sign In with Google
Sign In with Linked In
OR

Login to your account below

Forgotten Password? Sign Up

Create New Account!

Sign Up with Facebook
Sign Up with Google
Sign Up with Linked In
OR

Fill the forms below to register

All fields are required. Log In

Retrieve your password

Please enter your username or email address to reset your password.

Log In
No Result
View All Result
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú

© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group