• About
  • Advertise
  • Careers
  • Contact
Saturday, May 24, 2025
  • Login
  • Register
No Result
View All Result
NEWSLETTER
ÌWÉ ÌRÒYÌN YORÙBÁ
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • All
    • ijamba oko
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọ̀rọ̀ ìdílé
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÌJÀMBÁ INÁ LỌ́TÙN-ÚN LÓSÌ.

    ỌKỌ DÁNÁ SUN ÌYÀWÓ ÀTI ÀWỌN ỌMỌ RẸ̀ MẸ́TA NÍ ABIA.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN ỌMỌ ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN ṢEKÚ PA BENJAMIN NÍ IKORODU.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    GIFT FI EYÍN GÉ OKÓ OLÓLÙFẸ́ RẸ̀ BỌ́ SÍLẸ̀.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ILÉ IṢẸ́ OLÓGUN YAN ALUKORO OBÌNRIN ÀKỌ́KỌ́.

    ÀWỌN JÀǸDÙKÚ AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÀWỌN ỌLỌ́PÀÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ANAMBRA.

    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • All
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    ỌKÙNRIN MỌ́KÀNLÉLÓGÚN LÓ BÁ ÌYÀWÓ MI LÒ PỌ̀- ÌJỌBA LANDE

    MI Ò NÍ LE BÁ BABA TEE ṢIṢẸ́ PỌ̀ – ÌJỌBA LANDE.

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    Ramadan Kareem!

    Ramadan Kareem!

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • All
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
    • Oge Ṣiṣe
    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÌJÀMBÁ INÁ LỌ́TÙN-ÚN LÓSÌ.

    ỌKỌ DÁNÁ SUN ÌYÀWÓ ÀTI ÀWỌN ỌMỌ RẸ̀ MẸ́TA NÍ ABIA.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN ỌMỌ ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN ṢEKÚ PA BENJAMIN NÍ IKORODU.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    GIFT FI EYÍN GÉ OKÓ OLÓLÙFẸ́ RẸ̀ BỌ́ SÍLẸ̀.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ILÉ IṢẸ́ OLÓGUN YAN ALUKORO OBÌNRIN ÀKỌ́KỌ́.

    ÀWỌN JÀǸDÙKÚ AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÀWỌN ỌLỌ́PÀÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ANAMBRA.

    ONÍRÒYÌN KAN DÁKẸ́ NÍBI TÓ TI Ń MÚRA ÀTI KA ÌRÒYÌN.

    ONÍRÒYÌN KAN DÁKẸ́ NÍBI TÓ TI Ń MÚRA ÀTI KA ÌRÒYÌN.

    Trending Tags

    • Golden Globes
    • Mr. Robot
    • MotoGP 2017
    • Climate Change
    • Flat Earth
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • All
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÌPÍNLẸ̀ KWARA.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ALÁÀFIN YAN OSUNTOLA NÍ OLÙBÁDÁMỌ̀RÀN PÀTÀKÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    Ewì

    Ewì.

    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • All
    • ijamba oko
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọ̀rọ̀ ìdílé
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÌJÀMBÁ INÁ LỌ́TÙN-ÚN LÓSÌ.

    ỌKỌ DÁNÁ SUN ÌYÀWÓ ÀTI ÀWỌN ỌMỌ RẸ̀ MẸ́TA NÍ ABIA.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN ỌMỌ ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN ṢEKÚ PA BENJAMIN NÍ IKORODU.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    GIFT FI EYÍN GÉ OKÓ OLÓLÙFẸ́ RẸ̀ BỌ́ SÍLẸ̀.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ILÉ IṢẸ́ OLÓGUN YAN ALUKORO OBÌNRIN ÀKỌ́KỌ́.

    ÀWỌN JÀǸDÙKÚ AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÀWỌN ỌLỌ́PÀÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ANAMBRA.

    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • All
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    ỌKÙNRIN MỌ́KÀNLÉLÓGÚN LÓ BÁ ÌYÀWÓ MI LÒ PỌ̀- ÌJỌBA LANDE

    MI Ò NÍ LE BÁ BABA TEE ṢIṢẸ́ PỌ̀ – ÌJỌBA LANDE.

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    Ramadan Kareem!

    Ramadan Kareem!

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • All
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
    • Oge Ṣiṣe
    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÌJÀMBÁ INÁ LỌ́TÙN-ÚN LÓSÌ.

    ỌKỌ DÁNÁ SUN ÌYÀWÓ ÀTI ÀWỌN ỌMỌ RẸ̀ MẸ́TA NÍ ABIA.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN ỌMỌ ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN ṢEKÚ PA BENJAMIN NÍ IKORODU.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    GIFT FI EYÍN GÉ OKÓ OLÓLÙFẸ́ RẸ̀ BỌ́ SÍLẸ̀.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ILÉ IṢẸ́ OLÓGUN YAN ALUKORO OBÌNRIN ÀKỌ́KỌ́.

    ÀWỌN JÀǸDÙKÚ AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÀWỌN ỌLỌ́PÀÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ANAMBRA.

    ONÍRÒYÌN KAN DÁKẸ́ NÍBI TÓ TI Ń MÚRA ÀTI KA ÌRÒYÌN.

    ONÍRÒYÌN KAN DÁKẸ́ NÍBI TÓ TI Ń MÚRA ÀTI KA ÌRÒYÌN.

    Trending Tags

    • Golden Globes
    • Mr. Robot
    • MotoGP 2017
    • Climate Change
    • Flat Earth
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • All
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÌPÍNLẸ̀ KWARA.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ALÁÀFIN YAN OSUNTOLA NÍ OLÙBÁDÁMỌ̀RÀN PÀTÀKÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    Ewì

    Ewì.

    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú
No Result
View All Result
ÌWÉ ÌRÒYÌN YORÙBÁ
No Result
View All Result
Home Ètò ẹ̀kọ́

ÒFIN NI OOO, OLÙKỌ́ Ò GBỌDỌ̀ LO ẸGBA MỌ́ NÍ GBOGBO ILÉ ÌWÉ TÓ WÀ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ÈKÓ

OWÓ ÌTANRÀN TÀBÍ Ẹ̀WỌ̀N NI FÚN OLÙKỌ́ TÓ BÁ LO ẸGBA

by Omobolanle Rabiu
March 9, 2025
in Ètò ẹ̀kọ́, Ìròyìn Tó Gbòde
0
ÒFIN NI OOO, OLÙKỌ́ Ò GBỌDỌ̀ LO ẸGBA MỌ́ NÍ GBOGBO ILÉ ÌWÉ TÓ WÀ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ÈKÓ
0
SHARES
1
VIEWS
Pín Lórí FacebookPín Lórí ThreadsPín Lórí TwitterPín Lórí Bluesky

Ní ọ̀sẹ̀ tó kọjá yìí ni Kọmíṣánnà fùn ètò ẹ̀kọ́ ní ìpínẹ̀ Èkó, Alàgbà JAMIU ALLI-BALOGUN ní ó di èèwọ̀ fún gbogbo olùkọ́ yálà ní ilé ìwé ìjọba tàbí aládàáni láti máa yọ ẹgba kiri, olùkọ́ kò sì gbọdọ̀ lo ẹgba, olùkọ́ tí ó bá jẹ̀bi ẹ̀sùn yìí jó fi aṣọ pénpé ro oko ọba tàbí san owó ìtanràn. Kọmíṣánnà ní kàkà kí olùkọ́ máa lo ẹgba, ọ̀rọ̀ ìyànjú tí àwọn eléèbó mọ̀ sí COUSELING ni kí wọ́n máa ṣe fún àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ nítorí ọ̀rọ̀ lọmọ elétí n jẹ. Kọ́míṣánnà ní kí àwọn olùkọ́ máa fún àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ ní ìmọ̀ràn lóòrè-kóòrè, fún ìdí èyí, ẹgba lílò ní ilé ìwé wa ní ìpínlẹ̀ Èkó ti di òfin báyìí nítorí ìlú tí kò sí òfin, ẹ̀ṣẹ̀ kò sí níbẹ̀. Èèwọ̀ ni láti máa na Akẹ́kọ̀ọ́ lẹ́gba, a kò faramọ́ ṣíṣe Akẹ́kọ̀ọ́ léṣe, àpá kò sì gbọdọ̀ sí lára ọmọ dípò lílo ẹgba ní ilé ìwé, olùkọ́ le è ní kí wọ́n kúnlẹ̀-káwó sókè-dijú tàbí tún ìyàrá ìkàwé wọn ṣe nípa ṣíṣa ilẹ̀ àyíká.
Lọ́dún 2022, àbádòfin jíjínà sí ẹgba lílò nílé ìwé yìí gbilẹ̀ bí ọ̀wàrà òjò ní ìpínlẹ̀ Èkó lábẹ́ ètò ẹ̀tọ́ ọmọdé láti le è gbógun ti lílo ọmọdé nílòkulò. Kọmíṣánnà JAMIU ALLI-BALOGUN ní ìwọ̀ntún-wọ̀nsì ni kí ìbáwí jẹ́ fún ọmọdé àgàgà àwọn ògo wẹẹrẹ, ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó kò sọ wí pé kí a máa wo ọmọdé níran, bí wọ́n bá hù ìwà tí kò dára àmọ́ ìbáwí kò gbọdọ̀ pọ̀jù, díẹ̀-díẹ̀ ló gbọ́dọ̀ jẹ́ nítorí Yorùbá wọ́n ní ‘ọwọ́ kótópó la fi n bá ọmọdé wí’. Kọmíṣánnà JAMIU ALLI-BALOGUN ní a mọ̀ dájú gbangba-gbàngbà pé yóò tó bí ọdún márùn ún kí òfin tó gbilẹ̀ káàkiri ilé ìwé ní ìpínlẹ̀ Èkó síbẹ̀, ohun tí a fẹ́ nìyí, ó sì ti di òfin. ọ́míṣánnà ALLI-BALOGUN ní ìdí nìyí tí ìjọba Ìpínlẹ̀ Èkó ṣe n gba àwọn olùkó tó kájú òṣùwọ̀n, àwọn olùkọ́ fọ́nyánmu-kẹ́rù-ó-b’ẹ̀kọ, àwọn olùkọ́ tó tó gbangba sùn lọ́yẹ́, àwọn tó kọ́ṣẹ́ ìkọ́ni yanjú tí wọ́n sì jẹ́ olùkọ́ aláfọkànsìn. Lótòótọ́, àwọn olùkọ́ mìíràn kò rí bákan náà, wọ́n le è ṣe ọmọ léṣe pẹ̀lú ìbínú. Ìjìyà nlá bí ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́fà àti owó ìtanràn ní ẹnikẹ́ni tí adé ìwà yìí bá ṣímọ́ lórí.
Awuyewuye ni àbádòfin yìí dá sílẹ̀ gbáà! Ọ̀kan lára awuyewuye yìí ni ti ọ̀gá àgbà fún àjọ INTERNATIONAL TRAINING RESEARCH AND ADVOCACY PROJECT ( INTRAP) DR. MACPHELELANE EJAH ti fi ẹ̀họ́nnú rẹ̀ hàn lórí àbádòfin ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó lórí dídènà ìbáwí àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ ní ilé ìwé ìpínlẹ̀ Èkó yálà ti ìjọba tàbí ti Aládàáni ní ìpínlẹ̀ Èkó láti ọjọ́ rú, ọ̀sẹ̀ tó kọjá lọ́hùn ún.JAMIU ALLI-BALOGUN ní ó di èèwọ̀ fún gbogbo olùkọ́ yálà ní ilé ìwé ìjọba tàbí aládàáni láti máa yọ ẹgba kiri, olùkọ́ kò sì gbọdọ̀ lo ẹgba, olùkọ́ tí ó bá jẹ̀bi ẹ̀sùn yìí jó fi aṣọ pénpé ro oko ọba tàbí san owó ìtanràn. Kọmíṣánnà ní kàkà kí olùkọ́ máa lo ẹgba, ọ̀rọ̀ ìyànjú tí àwọn eléèbó mọ̀ sí COUSELING ni kí wọ́n máa ṣe fún àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ nítorí ọ̀rọ̀ lọmọ elétí n jẹ. Kọ́míṣánnà ní kí àwọn olùkọ́ máa fún àwọn Akẹ́kọ̀ọ́ ní ìmọ̀ràn lóòrè-kóòrè, fún ìdí èyí, ẹgba lílò ní ilé ìwé wa ní ìpínlẹ̀ Èkó ti di òfin báyìí nítorí ìlú tí kò sí òfin, ẹ̀ṣẹ̀ kò sí níbẹ̀. Èèwọ̀ ni láti máa na Akẹ́kọ̀ọ́ lẹ́gba, a kò faramọ́ ṣíṣe Akẹ́kọ̀ọ́ léṣe, àpá kò sì gbọdọ̀ sí lára ọmọ dípò lílo ẹgba ní ilé ìwé, olùkọ́ le è ní kí wọ́n kúnlẹ̀-káwó sókè-dijú tàbí tún ìyàrá ìkàwé wọn ṣe nípa ṣíṣa ilẹ̀ àyíká.
Lọ́dún 2022, àbádòfin jíjínà sí ẹgba lílò nílé ìwé yìí gbilẹ̀ bí ọ̀wàrà òjò ní ìpínlẹ̀ Èkó lábẹ́ ètò ẹ̀tọ́ ọmọdé láti le è gbógun ti lílo ọmọdé nílòkulò. Kọmíṣánnà JAMIU ALLI-BALOGUN ní ìwọ̀ntún-wọ̀nsì ni kí ìbáwí jẹ́ fún ọmọdé àgàgà àwọn ògo wẹẹrẹ, ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó kò sọ wí pé kí a máa wo ọmọdé níran, bí wọ́n bá hù ìwà tí kò dára àmọ́ ìbáwí kò gbọdọ̀ pọ̀jù, díẹ̀-díẹ̀ ló gbọ́dọ̀ jẹ́ nítorí Yorùbá wọ́n ní ‘ọwọ́ kótópó la fi n bá ọmọdé wí’. Kọmíṣánnà JAMIU ALLI-BALOGUN ní a mọ̀ dájú gbangba-gbàngbà pé yóò tó bí ọdún márùn ún kí òfin tó gbilẹ̀ káàkiri ilé ìwé ní ìpínlẹ̀ Èkó síbẹ̀, ohun tí a fẹ́ nìyí, ó sì ti di òfin. ọ́míṣánnà ALLI-BALOGUN ní ìdí nìyí tí ìjọba Ìpínlẹ̀ Èkó ṣe n gba àwọn olùkó tó kájú òṣùwọ̀n, àwọn olùkọ́ fọ́nyánmu-kẹ́rù-ó-b’ẹ̀kọ, àwọn olùkọ́ tó tó gbangba sùn lọ́yẹ́, àwọn tó kọ́ṣẹ́ ìkọ́ni yanjú tí wọ́n sì jẹ́ olùkọ́ aláfọkànsìn. Lótòótọ́, àwọn olùkọ́ mìíràn kò rí bákan náà, wọ́n le è ṣe ọmọ léṣe pẹ̀lú ìbínú. Ìjìyà nlá bí ẹ̀wọ̀n oṣù mẹ́fà àti owó ìtanràn ní ẹnikẹ́ni tí adé ìwà yìí bá ṣímọ́ lórí.

EJAH MACPHELANE ní kìí ṣe àṣà àti ìṣe ọmọ adúláwọ̀, níṣe là n kọ́ àṣà àtọ̀húnrìnwá fi bo àṣà wa mọ́lẹ̀, a ti gbé àṣà àtọ̀húnrìnwá gorí àṣà ti wa eléyìí sì tàbùkù bá ilẹ̀ Nàìjíríà púpọ̀-púpọ̀ jù. EJAH MACPHELANE ní àbájáde òfin yìí kò le è fi ara rọ, ipa búburú ni yóò jẹ́ fún àwọn ọmọ wa. Alàgbà EJAH MACPHELANE sọ pé :
Nínú ilé pàápàá, òbí n bá ọmọdé wí, ẹgba kìí pa ọmọ, ó n mú ọmọdé gbọ́n ni. Kò burú, kò sì bàjẹ́ bí a bá n lo ẹgba ní ilé ìwé náà. Àṣà àti ìṣe wa ni ìbáwí, ẹ̀sìn àti ìwòye ẹ̀dá pàápàá kò lòdì sí ìbáwí. Kò gbọdọ̀ di ìgbà yìí, kí a ní kò jọọ́, kò ṣe é ṣe tàbí kò sí ohun tó n jẹ́ bẹ́ẹ̀, kí a wá ti ìdayìí gùnlé òfin kan tí kò ní oore nínú, ká kọ ẹgba nínà sílẹ̀ láì sí gbé ìgbésẹ̀ Akin láti mọ ìdí àti ìtumọ̀ ọ̀nà tí wọ́ wá. EJAH MACPHELANE n tẹpele mọ́ ọ́n pé èyí kìí ṣe àṣà àti ẹ̀sìn ilẹ̀ Nàìjíríà rárá, àṣà àjòjì àti àtọ̀húnrìnwá ni èyí.
EJAH MACPHELANE ní kò yẹ ká kọ ìbáwí pátápátá ní ilé ìwé ìpínlẹ̀ Èkó, nnkan tó yẹ ní ṣíṣe ni kí òfin dé bí a tilè lo ẹgba, ìyẹn ni pé kò gbọdọ̀ sí ìbáwí tí yóò mú àpá wá sára ọmọ tàbí kí ó la ẹ̀mí lọ.Ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó gbọdọ̀ rí i pé àwọn olùkọ́ tó dángájíá ní wọ́n gbà sẹ́nu iṣẹ́. EJAH MACPHELANE ní ohun tó dàra ni láti máa gba ọmọdé ní ìmọ̀ràn bí wọ́n bá ṣe nnkan tí kò dára ṣùgbọ́n èyí kò le è ṣe iṣẹ́ tí ẹgba yóò ṣe nínú ayé ọmọ tó ní ìpánlè. EJAH tún tẹ̀síwájú pé : bí i kání ìjọba ìpínlẹ̀ Èkó kò mọ láabi tí òfin yìí yóò dá sílẹ̀ lọ́jọ́ iwàjú? Ní gbogbo ilé ìwé ilẹ̀ Nàìjíríà, ìgbaniníyànjú máa n wáyé fún Akẹ́kọ̀ọ́ lóòrè-kóòrè lórí bí Akẹ́kọ̀ọ́ yóò ti yan iṣẹ́ tó fẹ́ ṣe lọ́jọ́ iwájúú , kìí ṣe láti tọ́ Akẹ́kọ̀ọ́ sọ́nà ìwà àìtọ́ rẹ̀. Ìgbnaniníyànjú àti ẹgba nínà ló jọ n ṣiṣẹ́ papọ̀ mọ́ra wọn nítorí bí ọ̀kan kò bá sí, èkejì kò le è ṣe.
Bí olùkọ́ bà tilẹ̀ n mú ẹgba kiri inú ọgbà ilé ìwé, wọn kìí lò ó lọ́pọ̀ ìgbà ṣùgbọ́n ìtọ́kasí ni fún Akẹ́kọ̀ọ́ láti jẹ́ kí orí Akẹ́kọ̀ọ́ pé, kí wọ́n ṣì ṣọ́ra ṣe.
Ọ̀jọ̀gbọ́n AYODEJI OWOLABI ti ifáfitì CALABAR náà ṣe àfikún ọ̀rọ̀ EJAH MACPHELANE pé : Bí kò bá sí ìbáwí tó múnádóko nílé ìwé, àwọn ọmọ wa yóò di arúfin lọ́jọ́ iwájú, ìwọ̀ntún-wọ̀nsì ni kí gbogbo rẹ̀ jẹ́, kò gbọdọ̀ la ẹ̀mí lọ tàbí ṣe Akẹ́kọ̀ọ́ ní ìjàmbá. Ọ̀jọ́gbọ́n AYODJI ní ‘Mi ò lòdì sí àmọ̀ràn Akẹ́kọ̀ọ́ ní gbogbo ilé ìwé, síbẹ̀, lílo ẹgba gbọ́dọ̀ wá.

Facebook Comments Box
Tags: #alli-balogun#commissionerforeducation#ejahmacphelane#iweiroyinyoruba#Lagosupdate
Omobolanle Rabiu

Omobolanle Rabiu

Next Post
TÈTÈ WỌ́ IGI LÉ ẸJỌ́ TÓ O DÁ FÚN SẸNẸTỌ NATASHIA , BÓ Ò BÁ FẸ́ RÍ ÌBÍNÚ ÒFIN: SERAP

TÈTÈ WỌ́ IGI LÉ ẸJỌ́ TÓ O DÁ FÚN SẸNẸTỌ NATASHIA , BÓ Ò BÁ FẸ́ RÍ ÌBÍNÚ ÒFIN: SERAP

Recommended

Ìròyìn Jákèjádò.

Ìròyìn Jákèjádò.

2 months ago
ÀJỌ MURIC NA ÌKA ÀBÙKÙ SÍ ÀWỌN OLÓṢÈLÚ ILẸ̀ YÌÍ LÓRÍ BÍ WỌ́N ṢE ṢÙGBÁ ÌWÀ LÁABI NÍLẸ̀ NÀÌJÍRÍÀ.

ÀJỌ MURIC NA ÌKA ÀBÙKÙ SÍ ÀWỌN OLÓṢÈLÚ ILẸ̀ YÌÍ LÓRÍ BÍ WỌ́N ṢE ṢÙGBÁ ÌWÀ LÁABI NÍLẸ̀ NÀÌJÍRÍÀ.

3 months ago

Popular News

  • ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • ỌKỌ DÁNÁ SUN ÌYÀWÓ ÀTI ÀWỌN ỌMỌ RẸ̀ MẸ́TA NÍ ABIA.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0

Connect with us

Newsletter

Lorem ipsum dolor sit amet, consectetuer adipiscing elit. Aenean commodo ligula eget dolor.
SUBSCRIBE

Category

Site Links

  • Register
  • Log in
  • Entries feed
  • Comments feed
  • WordPress.org

About Us

We bring you the best Premium WordPress Themes that perfect for news, magazine, personal blog, etc. Check our landing page for details.

  • About
  • Advertise
  • Careers
  • Contact

© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group

Welcome Back!

Sign In with Facebook
Sign In with Google
Sign In with Linked In
OR

Login to your account below

Forgotten Password? Sign Up

Create New Account!

Sign Up with Facebook
Sign Up with Google
Sign Up with Linked In
OR

Fill the forms below to register

All fields are required. Log In

Retrieve your password

Please enter your username or email address to reset your password.

Log In
No Result
View All Result
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú

© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group