• About
  • Advertise
  • Careers
  • Contact
Friday, May 23, 2025
  • Login
  • Register
No Result
View All Result
NEWSLETTER
ÌWÉ ÌRÒYÌN YORÙBÁ
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • All
    • ijamba oko
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọ̀rọ̀ ìdílé
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÌJÀMBÁ INÁ LỌ́TÙN-ÚN LÓSÌ.

    ỌKỌ DÁNÁ SUN ÌYÀWÓ ÀTI ÀWỌN ỌMỌ RẸ̀ MẸ́TA NÍ ABIA.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN ỌMỌ ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN ṢEKÚ PA BENJAMIN NÍ IKORODU.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    GIFT FI EYÍN GÉ OKÓ OLÓLÙFẸ́ RẸ̀ BỌ́ SÍLẸ̀.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ILÉ IṢẸ́ OLÓGUN YAN ALUKORO OBÌNRIN ÀKỌ́KỌ́.

    ÀWỌN JÀǸDÙKÚ AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÀWỌN ỌLỌ́PÀÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ANAMBRA.

    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • All
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    ỌKÙNRIN MỌ́KÀNLÉLÓGÚN LÓ BÁ ÌYÀWÓ MI LÒ PỌ̀- ÌJỌBA LANDE

    MI Ò NÍ LE BÁ BABA TEE ṢIṢẸ́ PỌ̀ – ÌJỌBA LANDE.

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    Ramadan Kareem!

    Ramadan Kareem!

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • All
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
    • Oge Ṣiṣe
    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÌJÀMBÁ INÁ LỌ́TÙN-ÚN LÓSÌ.

    ỌKỌ DÁNÁ SUN ÌYÀWÓ ÀTI ÀWỌN ỌMỌ RẸ̀ MẸ́TA NÍ ABIA.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN ỌMỌ ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN ṢEKÚ PA BENJAMIN NÍ IKORODU.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    GIFT FI EYÍN GÉ OKÓ OLÓLÙFẸ́ RẸ̀ BỌ́ SÍLẸ̀.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ILÉ IṢẸ́ OLÓGUN YAN ALUKORO OBÌNRIN ÀKỌ́KỌ́.

    ÀWỌN JÀǸDÙKÚ AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÀWỌN ỌLỌ́PÀÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ANAMBRA.

    ONÍRÒYÌN KAN DÁKẸ́ NÍBI TÓ TI Ń MÚRA ÀTI KA ÌRÒYÌN.

    ONÍRÒYÌN KAN DÁKẸ́ NÍBI TÓ TI Ń MÚRA ÀTI KA ÌRÒYÌN.

    Trending Tags

    • Golden Globes
    • Mr. Robot
    • MotoGP 2017
    • Climate Change
    • Flat Earth
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • All
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÌPÍNLẸ̀ KWARA.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ALÁÀFIN YAN OSUNTOLA NÍ OLÙBÁDÁMỌ̀RÀN PÀTÀKÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    Ewì

    Ewì.

    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • All
    • ijamba oko
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọ̀rọ̀ ìdílé
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÌJÀMBÁ INÁ LỌ́TÙN-ÚN LÓSÌ.

    ỌKỌ DÁNÁ SUN ÌYÀWÓ ÀTI ÀWỌN ỌMỌ RẸ̀ MẸ́TA NÍ ABIA.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN ỌMỌ ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN ṢEKÚ PA BENJAMIN NÍ IKORODU.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    GIFT FI EYÍN GÉ OKÓ OLÓLÙFẸ́ RẸ̀ BỌ́ SÍLẸ̀.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ILÉ IṢẸ́ OLÓGUN YAN ALUKORO OBÌNRIN ÀKỌ́KỌ́.

    ÀWỌN JÀǸDÙKÚ AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÀWỌN ỌLỌ́PÀÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ANAMBRA.

    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • All
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    ỌKÙNRIN MỌ́KÀNLÉLÓGÚN LÓ BÁ ÌYÀWÓ MI LÒ PỌ̀- ÌJỌBA LANDE

    MI Ò NÍ LE BÁ BABA TEE ṢIṢẸ́ PỌ̀ – ÌJỌBA LANDE.

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    Ramadan Kareem!

    Ramadan Kareem!

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • All
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
    • Oge Ṣiṣe
    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÌJÀMBÁ INÁ LỌ́TÙN-ÚN LÓSÌ.

    ỌKỌ DÁNÁ SUN ÌYÀWÓ ÀTI ÀWỌN ỌMỌ RẸ̀ MẸ́TA NÍ ABIA.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN ỌMỌ ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN ṢEKÚ PA BENJAMIN NÍ IKORODU.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    GIFT FI EYÍN GÉ OKÓ OLÓLÙFẸ́ RẸ̀ BỌ́ SÍLẸ̀.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ILÉ IṢẸ́ OLÓGUN YAN ALUKORO OBÌNRIN ÀKỌ́KỌ́.

    ÀWỌN JÀǸDÙKÚ AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÀWỌN ỌLỌ́PÀÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ANAMBRA.

    ONÍRÒYÌN KAN DÁKẸ́ NÍBI TÓ TI Ń MÚRA ÀTI KA ÌRÒYÌN.

    ONÍRÒYÌN KAN DÁKẸ́ NÍBI TÓ TI Ń MÚRA ÀTI KA ÌRÒYÌN.

    Trending Tags

    • Golden Globes
    • Mr. Robot
    • MotoGP 2017
    • Climate Change
    • Flat Earth
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • All
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÌPÍNLẸ̀ KWARA.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ALÁÀFIN YAN OSUNTOLA NÍ OLÙBÁDÁMỌ̀RÀN PÀTÀKÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    Ewì

    Ewì.

    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú
No Result
View All Result
ÌWÉ ÌRÒYÌN YORÙBÁ
No Result
View All Result
Home Ààyè Olóòtú

MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

Femi Adio Wonder ṣe àlàyé ipò àìlera rẹ̀.

by Adeola Olanrewaju
March 31, 2025
in Ààyè Olóòtú, Fiimu ati Nollywood, Ìgbé-Ayé, Ìlera, Ìròyìn, Ìròyìn Tó Gbòde, Ọ̀rọ̀ ìdílé
0
MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.
0
SHARES
12
VIEWS
Pín Lórí FacebookPín Lórí ThreadsPín Lórí TwitterPín Lórí Bluesky

Agbóhùnsáfẹ́fẹ́ kan tí ó pe orúkọ ara rẹ̀ ní Femi Adio Wonder ti bá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀ lórí àìsàn ìtọ̀ ṣúgà tó ń bá a jà, ọ̀rọ̀ náà gba omijé lójú ẹni.
Adio wí pé ọdún mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n tí òun ti ń ṣiṣẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ àti olùpolówó sinímá agbéléwò rèé. Adio a máa ṣe ètò lórí rédíò Èkó ìgbà náà tó di Eko FM nísìn yìí, bákan náà ló ti ṣiṣẹ́ nílé iṣẹ́ rédíò Paramount ní Abẹ́òkùta.

Nípa àìlera rẹ̀:

Adio ṣe àlàyé pé ara òun ti ń fún òun ní àpẹẹrẹ àmọ́ òun kò fi ọkàn síi títí tó fi bu rẹ́kẹ, àìsàn ìtọ̀ ṣúgà ni ó ń bá Adio fínra tó sì ti run àwọn ohun ìní rẹ̀ ló lórí.
Adio ní òun ti ta gbogbo ilé òun àfi ọ̀kan tó wà ní Abule Oko tí òun ń gbé, gbogbo ọkọ̀ náà ti lọ sí i.
Adio wí pé akẹgbẹ́ òun ní kí òun ó má dé àìsàn náà mọ́ra àmọ́ ojú ń ti òun láti ké gbàjarè nítorí pé òun máa ń fún àwọn èèyàn ni tẹ́lẹ̀ òun kò sì fẹ́ di alágbe. Nígbà tí àbúrò Gbenga Adeboye ìyẹn Seun Adeboye náà tún wá kàn sí òun pé kí òun ó ké gbàjarè ni ó mú kí òun ó sọ̀rọ̀ síta lórí àìsàn náà.
Adio ṣe àlàyé pé ìnira tí òun ń kojú náà pọ̀ gan-an, ó ti lé lọ́dún mẹ́ta tí òun ti ṣiṣẹ́ gbẹ̀yìn, ó ní tí òun bá rìn báyìí, ṣe ni yóò dàbí ìgbà tí òun ń tẹ ẹ̀kúfọ́ ìgò mọ́lẹ̀ ni, ìnira náà pọ̀ gan-an.
Adio wí pé ẹkún lòun máa ń fi ojoojúmọ́ sun, ó wí pé nǹkan nira fún òun gan-an láti bíi ọdún mẹ́ta sẹ́yìn, ó ní òun kò lérò pé òun le wà ní irú ipò náà. Àwọn èèyàn máa ń wí pé èèyàn ire lòun kò yẹ kí irú èyí tọ́ sí òun.

Àwọn ìrànlówọ́ tó ti rí gbà:

Adio ṣe àlàyé pé àwọn èèyàn sa ipá wọn fún òun, ó ní òun a máa rí àwọn owó dị́ẹ̀díẹ̀ gbà lọ́wọ́ àwọn tí wọ́n bá wá kí òun, ẹlòmíràn á fún òun ní ẹgbẹ̀rún márùn-ún náírà, ẹgbẹ̀rún méjì náírà, ẹgbẹ̀rún kan náírà, nígbà mìíràn, ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta náírà.
Ó ní òun mọ̀ pé kálukú ló ní bùkátà tirẹ̀, òun kò sì le kó bùkátà àìsàn òun bá ẹlòmíràn ni ó ṣ e ń ba òun lọ́kàn jẹ́.
Adio dúpẹ́ lọ́wọ́ Wasiu Alabi Pasuma fún ìrànlọ́wọ́ rẹ̀, ó ní ó fún òun ní mílíọ́nù méjì náírà, ó ní òun dúpẹ́ fún ìfẹ́ tó fi hàn sí òun náà. Bákan náà ló dúpẹ́ lọ́wọ́ Alhaji Fatai Bantale, Asiwaju Akeem Enudunjuyo àti àwọn mìíràn tí kò le dárúkọ wọn tán. Adio dúpẹ́ lọ́wọ́ wọn ó sì ṣe àdúrà fún wọn pé wọn kò ní fi irú rẹ̀ gbà á.

Báwo ni o ṣe ń gbọ́ bùkátà rẹ?

Adio wí pé èyí gangan ló ń jẹ́ òun. Ibi tó le sí gan-an ni èyí, àtigbọ́ bùkátà nira gidigidi nítorí pé òun kò ṣiṣẹ́, ohun tí àwọn èèyàn ń fún òun ni òun fi ń gbéra.
Ó wí pé yàtọ̀ sí owó tí òun fi ń tọ́jú àìsà ìtọ̀ ṣúgà náà, àwọn bùkátà mìíràn wà nílẹ̀ rẹpẹtẹ tí òun kò le gbé. Ó ní ibi tó burú sí ni pé àwọn bùkátà yìí kò le tán.
Adio tẹ̀síwajú pé òun kò fẹ́ kí àwọn èèyàn ó pòṣé bí wọ́n bá rí ìpè òun ni òun ṣe ń ní ìrètí àti ìgbàgbọ́ nínú Ọlọ́run.

Ǹjẹ́ àìsàn yìí ti mú kí o ní ìdẹ́yẹsí láti ọ̀dọ̀ àwọn èèyàn?

Adio sọ̀rọ̀ lórí ìhà tí àwọn èèyàn kan kọ sí òun. Ó ní lójú òun, wọn yóò káàánú àmọ́ bí wọ́n bá ti kúrò lọ́dọ̀ òun ni wọn yóò yíhùn padà pé ta ló kó bá a?
Adio ní èyí ba òun nínú jẹ́ nítorí pé òun kò fìgbà kan ṣe abúrú tàbí hu ìwà ìkà sí èèyàn rí. Ó ní òun gbìyànjú àti ṣe ìrántí ìrìn àjò òun bóyá òun le rántí ìgbà tí òun ṣe ìkà sí èèyàn rí àmọ́ òun kò rántí ni òun ṣe rí ohun tí wọ́n ṣe yìí bíi ìwà ìkà.
Ọ̀rọ̀ rẹ̀ tẹ̀síwájú pé àwọn tí òun ti fìgbà kan ṣe ìrànwọ́ fún ni òun gbọ́ pé wọ́n ń sọ kiri pé kí àwọn èèyàn ó má ṣe ìrànwọ́ fún òun pé òun yóò fi owó náà mu ọtí ni.
Adio wí pé pẹ̀lú ipò tí òun wà yìí, ṣé ọtí ni òun yóò máa mu? ó wí pé ohun tó dun òun níbẹ̀ ni pé àwọn èèyàn tí wọ́n ti jẹ ata, epo àti iyọ̀ òun ni wọ́n ń sọ irú èyí nípa òun.
Adio ṣe àlàyé pé òtítọ́ ni òun dìmú o, òtítọ́ náà sì ni pé ẹni tó wà láyé ló ní àǹfàáni àtimọ ọ̀tá rẹ̀, òun yóò gbìyànjú láti du ẹ̀mí òun láti má kú.
Ó wí pé ìgbà tí Pasuma fún òun lówó náà ni ìkóríra náà pọ̀ síi, àwọn èèyàn náà fi àìdunnú wọn hàn sí mílíọ̀nù méjì náírà tí Pasuma fún òun wọ́n sì fẹ́ pín nínú rẹ̀.
Èyí ló mú kí òun ó kọminú pé ṣé lóòótọ́ ni àwọn èèyàn yìí nífẹ̀ẹ́ òun dénú àbí ọjọ́ ikú òun ni wọ́n ń retí.

Ńjẹ́ o rí mílíọ̀nù méjì náà ṣe ìtọ́jú ara rẹ?

Adio fèsì pé owó náà ká àwọn ìtọ́jú kèékèèkèé ni kò ká ojúlówó ìtọ́jú tí yóò ṣẹ́gun àìsàn náà.
Dọ́kítà wí pé kí òun ó lọ sí orílẹ̀-èdè India fún ìtọ́jú tó péye àmọ́ kò sí agbára.
Adio wí pé àìsàn náà burú débi pé gbogbo ara òun yóò dàbí ìgbà tí wọ́n bá dá iná síi, nígbà mìíràn, òun kò ní lókun kankan nínú.

Èló ni o nílò fún ìtọ́jú àìsàn yìí?

Adio wí pé ogún mílíọ̀nù náírà ni àwọn dọ́kítà bèèrè fún kí wọ́n le gbé òun lọ sí orílẹ̀-èdè India fún ìtọ́jú.

Facebook Comments Box
Tags: #iweiroyinyorubadiabeteshealthhealthchallengenewsnewsonlinepasuma
Adeola Olanrewaju

Adeola Olanrewaju

Next Post
Ìròyìn Jákèjádò.

Ìròyìn Jákèjádò.

Recommended

Ìròyìn Jákèjádò.

3 months ago
ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU YÓÒ ṢE ÌWÚRE ỌJỌ́ ÌBÍ RẸ̀ LÓNÌÍ.

ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU YÓÒ ṢE ÌWÚRE ỌJỌ́ ÌBÍ RẸ̀ LÓNÌÍ.

2 months ago

Popular News

  • ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • ỌKỌ DÁNÁ SUN ÌYÀWÓ ÀTI ÀWỌN ỌMỌ RẸ̀ MẸ́TA NÍ ABIA.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0

Connect with us

Newsletter

Lorem ipsum dolor sit amet, consectetuer adipiscing elit. Aenean commodo ligula eget dolor.
SUBSCRIBE

Category

Site Links

  • Register
  • Log in
  • Entries feed
  • Comments feed
  • WordPress.org

About Us

We bring you the best Premium WordPress Themes that perfect for news, magazine, personal blog, etc. Check our landing page for details.

  • About
  • Advertise
  • Careers
  • Contact

© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group

Welcome Back!

Sign In with Facebook
Sign In with Google
Sign In with Linked In
OR

Login to your account below

Forgotten Password? Sign Up

Create New Account!

Sign Up with Facebook
Sign Up with Google
Sign Up with Linked In
OR

Fill the forms below to register

All fields are required. Log In

Retrieve your password

Please enter your username or email address to reset your password.

Log In
No Result
View All Result
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú

© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group