• About
  • Advertise
  • Careers
  • Contact
Tuesday, May 13, 2025
  • Login
  • Register
No Result
View All Result
NEWSLETTER
ÌWÉ ÌRÒYÌN YORÙBÁ
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • All
    • ijamba oko
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọ̀rọ̀ ìdílé
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
    Àmì ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Nàìjíría

    ỌWỌ́ TẸ ONÍLÉ ÌTURA TÓ Ń PA ÀWỌN ARÌRÌNÀJÒ.

    ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU KÉDE ÌPÍNLẸ̀ RIVERS NÍ ÌPÍNLẸ̀ PÀJÁWÌRÌ.

    KO PỌN DANDAN FÚN MI LÁTI PADÀ SÍPÒ GÓMÌNÀ – SIMINALAYI FUBARA.

    ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ MẸ́TA LÓ JẸ́RÌÍ TAKO TIMILEHIN AJAYI NÍLÉ ẸJỌ́.

    ILÉ ẸJỌ́ YỌ̀ǸDA ÌYÓKÙ HAFSOH FÚN ÀWỌN ÒBÍ RẸ̀.

    WỌ́N TI ṢÁ ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́JÁDE MÉJÌ PA.

    WỌ́N TI ṢÁ ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́JÁDE MÉJÌ PA.

    ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN MÉJÌ GBÉNÁ WOJÚ ARA WỌN NÍ ÌPÍNLẸ̀ RIVERS.

    KÒ SÍ ÀÀYÈ FÚN ÀWỌN ADÁHUNṢE NÍLẸ̀ WA MỌ́ – ÀWỌN ARÁ ÌPÍNLẸ̀ RIVERS.

    ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU YÓÒ ṢE ÌWÚRE ỌJỌ́ ÌBÍ RẸ̀ LÓNÌÍ.

    ẸGBẸ̀RIN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ NI A TI PA LÁBẸ́ ÌṢEJỌBA BOLA AHMED TINUBU – MÍNÍSÍTÀ FÚN ÈTÒ ÀÀBÒ.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    A Ó FI ÒFIN GBÉ OLADIPUPO – ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    ÀWỌN ÒBÍ TOPE LÙ Ú PA NÍ ÒǸDÓ.

    ÀWỌN ÒBÍ TOPE LÙ Ú PA NÍ ÒǸDÓ.

    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • All
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    ỌKÙNRIN MỌ́KÀNLÉLÓGÚN LÓ BÁ ÌYÀWÓ MI LÒ PỌ̀- ÌJỌBA LANDE

    MI Ò NÍ LE BÁ BABA TEE ṢIṢẸ́ PỌ̀ – ÌJỌBA LANDE.

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    Ramadan Kareem!

    Ramadan Kareem!

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • All
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
    • Oge Ṣiṣe
    ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU KÉDE ÌPÍNLẸ̀ RIVERS NÍ ÌPÍNLẸ̀ PÀJÁWÌRÌ.

    KO PỌN DANDAN FÚN MI LÁTI PADÀ SÍPÒ GÓMÌNÀ – SIMINALAYI FUBARA.

    ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ MẸ́TA LÓ JẸ́RÌÍ TAKO TIMILEHIN AJAYI NÍLÉ ẸJỌ́.

    ILÉ ẸJỌ́ YỌ̀ǸDA ÌYÓKÙ HAFSOH FÚN ÀWỌN ÒBÍ RẸ̀.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    A Ó FI ÒFIN GBÉ OLADIPUPO – ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN AWAKỌ̀ BRT TÓ PA BAMISHE.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN AWAKỌ̀ BRT TÓ PA BAMISHE.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ PA ÀWỌN ÈÈYÀN TÓ LỌ SÌNKÚ ÀWỌN TÍ WỌ́N TI PA TẸ́LẸ̀.

    ARABÌNRIN KEMI KÚ TOYÚNTOYÚN NÍTORÍ KÒ NÍ ẸGBẸ̀RÚN LỌ́NÀ Ẹ̀Ẹ́DẸ́GBẸ̀TA NÁÍRÀ.

    NATASHA TỌRỌ ÀFORÍJÌ Ẹ̀DẸ LỌ́WỌ́ AKPABIO LÓRÍ Ẹ̀SÙN TÓ FI KÀN ÁN.

    ỌKỌ̀ ÀJÀGBÉ ELÉJÒ JÁBỌ́ LÓRÍ AFÁRÁ PEN CINEMA.

    ỌKỌ̀ ÀJÀGBÉ ELÉJÒ JÁBỌ́ LÓRÍ AFÁRÁ PEN CINEMA.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ỌWỌ́ ÀWỌN AGBÓFINRÓ TẸ ÀWỌN TÓ PA BULAMA NÍ GOMBE.

    Trending Tags

    • Golden Globes
    • Mr. Robot
    • MotoGP 2017
    • Climate Change
    • Flat Earth
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • All
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÌPÍNLẸ̀ KWARA.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ALÁÀFIN YAN OSUNTOLA NÍ OLÙBÁDÁMỌ̀RÀN PÀTÀKÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    Ewì

    Ewì.

    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • All
    • ijamba oko
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọ̀rọ̀ ìdílé
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
    Àmì ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Nàìjíría

    ỌWỌ́ TẸ ONÍLÉ ÌTURA TÓ Ń PA ÀWỌN ARÌRÌNÀJÒ.

    ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU KÉDE ÌPÍNLẸ̀ RIVERS NÍ ÌPÍNLẸ̀ PÀJÁWÌRÌ.

    KO PỌN DANDAN FÚN MI LÁTI PADÀ SÍPÒ GÓMÌNÀ – SIMINALAYI FUBARA.

    ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ MẸ́TA LÓ JẸ́RÌÍ TAKO TIMILEHIN AJAYI NÍLÉ ẸJỌ́.

    ILÉ ẸJỌ́ YỌ̀ǸDA ÌYÓKÙ HAFSOH FÚN ÀWỌN ÒBÍ RẸ̀.

    WỌ́N TI ṢÁ ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́JÁDE MÉJÌ PA.

    WỌ́N TI ṢÁ ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́JÁDE MÉJÌ PA.

    ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN MÉJÌ GBÉNÁ WOJÚ ARA WỌN NÍ ÌPÍNLẸ̀ RIVERS.

    KÒ SÍ ÀÀYÈ FÚN ÀWỌN ADÁHUNṢE NÍLẸ̀ WA MỌ́ – ÀWỌN ARÁ ÌPÍNLẸ̀ RIVERS.

    ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU YÓÒ ṢE ÌWÚRE ỌJỌ́ ÌBÍ RẸ̀ LÓNÌÍ.

    ẸGBẸ̀RIN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ NI A TI PA LÁBẸ́ ÌṢEJỌBA BOLA AHMED TINUBU – MÍNÍSÍTÀ FÚN ÈTÒ ÀÀBÒ.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    A Ó FI ÒFIN GBÉ OLADIPUPO – ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    ÀWỌN ÒBÍ TOPE LÙ Ú PA NÍ ÒǸDÓ.

    ÀWỌN ÒBÍ TOPE LÙ Ú PA NÍ ÒǸDÓ.

    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • All
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    ỌKÙNRIN MỌ́KÀNLÉLÓGÚN LÓ BÁ ÌYÀWÓ MI LÒ PỌ̀- ÌJỌBA LANDE

    MI Ò NÍ LE BÁ BABA TEE ṢIṢẸ́ PỌ̀ – ÌJỌBA LANDE.

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    Ramadan Kareem!

    Ramadan Kareem!

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • All
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
    • Oge Ṣiṣe
    ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU KÉDE ÌPÍNLẸ̀ RIVERS NÍ ÌPÍNLẸ̀ PÀJÁWÌRÌ.

    KO PỌN DANDAN FÚN MI LÁTI PADÀ SÍPÒ GÓMÌNÀ – SIMINALAYI FUBARA.

    ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ MẸ́TA LÓ JẸ́RÌÍ TAKO TIMILEHIN AJAYI NÍLÉ ẸJỌ́.

    ILÉ ẸJỌ́ YỌ̀ǸDA ÌYÓKÙ HAFSOH FÚN ÀWỌN ÒBÍ RẸ̀.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    A Ó FI ÒFIN GBÉ OLADIPUPO – ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    ARÁBÌNRIN FIJABI KÉ SÍ ILÉ ÌWÉ GÍGA BABCOCK LÁTI WÁ ỌMỌ RẸ̀ SÍTA.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN AWAKỌ̀ BRT TÓ PA BAMISHE.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN AWAKỌ̀ BRT TÓ PA BAMISHE.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ PA ÀWỌN ÈÈYÀN TÓ LỌ SÌNKÚ ÀWỌN TÍ WỌ́N TI PA TẸ́LẸ̀.

    ARABÌNRIN KEMI KÚ TOYÚNTOYÚN NÍTORÍ KÒ NÍ ẸGBẸ̀RÚN LỌ́NÀ Ẹ̀Ẹ́DẸ́GBẸ̀TA NÁÍRÀ.

    NATASHA TỌRỌ ÀFORÍJÌ Ẹ̀DẸ LỌ́WỌ́ AKPABIO LÓRÍ Ẹ̀SÙN TÓ FI KÀN ÁN.

    ỌKỌ̀ ÀJÀGBÉ ELÉJÒ JÁBỌ́ LÓRÍ AFÁRÁ PEN CINEMA.

    ỌKỌ̀ ÀJÀGBÉ ELÉJÒ JÁBỌ́ LÓRÍ AFÁRÁ PEN CINEMA.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ỌWỌ́ ÀWỌN AGBÓFINRÓ TẸ ÀWỌN TÓ PA BULAMA NÍ GOMBE.

    Trending Tags

    • Golden Globes
    • Mr. Robot
    • MotoGP 2017
    • Climate Change
    • Flat Earth
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • All
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÌPÍNLẸ̀ KWARA.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ALÁÀFIN YAN OSUNTOLA NÍ OLÙBÁDÁMỌ̀RÀN PÀTÀKÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    Ewì

    Ewì.

    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú
No Result
View All Result
ÌWÉ ÌRÒYÌN YORÙBÁ
No Result
View All Result
Home Ààyè Olóòtú

ILÉ ẸJỌ́ YỌ̀ǸDA ÌYÓKÙ HAFSOH FÚN ÀWỌN ÒBÍ RẸ̀.

Ìgbẹ́jọ́ ń tẹ̀ síwájú

by Adeola Olanrewaju
May 12, 2025
in Ààyè Olóòtú, Ìgbé-Ayé, Ìròyìn, Ìròyìn Agbègbè, Ìròyìn Tó Gbòde, Ọ̀rọ̀ Ààbò, Ọ̀rọ̀ ìdílé
0
ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ MẸ́TA LÓ JẸ́RÌÍ TAKO TIMILEHIN AJAYI NÍLÉ ẸJỌ́.
0
SHARES
4
VIEWS
Pín Lórí FacebookPín Lórí ThreadsPín Lórí TwitterPín Lórí Bluesky

Ilé ẹjọ́ gíga ìpínlẹ̀ Kwara tó fìkàlẹ̀ sí Ilorin ti pàṣẹ kí wọn ó yọ̀ǹda ìyókù Hafsoh fún àwọn òbí rẹ̀ láti lọ sin.
Adájọ́ Hannah Ajayi ló pàṣẹ yìí nìgbà tí agbẹjọ́rò ẹbí Hafsoh bèèrè fún ìyọ̀ǹda ìyókù Hafsoh kí wọn ó sin ín kí ẹ̀mí rẹ̀ ó le sinmi.
Adájọ́ Hannah wí pé òun kò ní àtakò sí ìbéèrè yií, ó wí pé òun bá àwọn ẹbí Hafsoh kẹ́dùn ó sì pàṣẹ kí àwọn ọlọ́pàá ó yọ̀ǹda ìyókù ọmọ náà fún àwọn òbí rẹ̀.

Ikú Hafsoh:

AbdulRahman ni orúkọ afurasí alápatà yìí, ìlú Ilorin ló tẹ̀dó sí, inú ilé rẹ̀ náà ló sọ di odò ẹran tó ti ń pa á kun ún. Èyí tó bu ú lọ́wọ́ yìí ni ti ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀ tó pa, Hafsoh lọ kí AbdulRahman nílé ni kò dé mọ́. Ìtọpipin àwọn ọlọ́pàá ni wọ́n fi mú AbdulRahman, ó ti pa ọmọ náà ó sì ti gé e níkèéníkèé sínú ike ọ̀dà ọlọ́mọrí.
Ó ti fojú ba ilé ẹjọ́ lẹ́ẹ̀kan níbi tó ti sọ pé òun kò jẹ̀bi, adájọ́ sì sún ìgbẹ́jọ́ rẹ̀ síwájú.

Lónìí ni ìgbẹ́jọ́ mìíràn wáyé lórí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí, gbogbo àwọn tí ọ̀rọ̀ kàn ni wọ́n péjú pésẹ̀ sílé ẹjọ́ náà níbi tí adájọ́ Hannah ti pàṣẹ kí wọn ó lọ sin àgékù ọmọ náà.

Ìṣẹ̀lẹ̀ méjì ló ṣẹlẹ̀ nínú oṣù Ẹrẹ́nà tí èyí ṣẹ̀, inú oṣù náà ni olórin ẹ̀mí kan náà gba ẹ̀mí lẹ́nu ọ̀rẹ́bìnrin rẹ̀.
A mú ìròyìn náà wá pé Akọrin ẹ̀mí ni Timilehin Ajayi, orí àfẹ́sọ́na rẹ̀; Salome Enejo ni wọ́n bá lọ́wọ́ rẹ̀ tí wọ́n sì bá àwọn ẹ̀ya ara yòókù tó ti gé lékìrìlékìrì sínú àpò nílé rẹ̀.
Ọjọ́ Àìkú ni ọjọ́ yìí, Timilehin gbé orí Salome sínú àpò, ìsìń ṣì ń lọ lọ́wọ́, olùjọ́sìn kan ló fura sí Timilehin pé ìrìn rẹ̀ mú ìfura dání bó ṣe ń lọ sí etídò kan tí kò jìnnà sílé ìjọsìn.
Ẹni yìí pe àwọn èèyàn mọ́ra, wọ́n sì tọ ipasẹ̀ rẹ̀, bí Timilehin ṣe rí wọn ló sọ àpò náà sódò. Wọ́n mú un pé kó yọ àpò náà kó sì tú u, ó feré gée àmọ́ wọ́n lé e mú, títú tí yóò tú àpo yìí, orí àfẹ́sọ́nà rẹ̀; Salome ni wọ́n bá nínú rẹ̀.
Ìdájọ́ ọwọ́ ni wọ́n fẹ́ ṣe fún un àmọ́ àwọn ọlọ́pàá gbà á kalẹ̀, lẹ́yìn náà ni wọ́n lọ tú ilé rẹ̀ tí wọ́n sì bá àwọn ẹ̀yà ara Salome nínú àpò méji.
Àwọn ẹbí Salome ṣe ìdámọ̀ ọmọ wọn, ọmọ ọdún mẹ́rìnlélógún ni Salome, àgùnbánirọ̀ sì ni pẹ̀lú.
Olùkọ́ni Bibeli ilé ìjọsìn náà; Caleb Umaru ṣe àlàyé fún àwọn ọlọ́pàá pé ọmọ ìjọ kan ló fura sí Timilehin nígbà tí ara rẹ̀ kò balẹ̀, ó ṣọ́ ọ títí tó fi dé etídò náà kí wọn ó tó wá mú un’
Lẹ́yìn ìgbà náà ni àwọn akọ̀ròyìn bá Timileyin Ajayi sọ̀rọ̀ pé báwo ni ó ṣe rí lára rẹ̀? Ẹ ka ohun tó wí ‘Timileyin Ajayi; akọrin ẹ̀mí tí ọwọ́ tẹ̀ nígbà tó pa Salome wí pé òun kò kábàámọ̀ pé òun pa ọmọbìnrin náà rárá, òun pa á òun pa á náà ni kò sí bàbàrà kankan níbẹ̀, Timilehin ní kí ẹ yé pọ́n jẹ̀bẹ̀ lákìísà.
Àwọn akọ̀ròyìn bá Timileyin sọ̀rọ̀ pé báwo ni ó ṣe rí lára rẹ̀ nígbà tí wọ́n mú un fún ìpànìyàn àti pé báwo ni ó ṣe rí lára rẹ̀ pé ó pààyàn?
Timilehin kó àlàyé ṣe, ó kó ẹjọ́ rò pé kò sí nǹkan bàbàrà nínú pé òun pa Salome o, ó ti lé lọ́dún kan tí òun ti ń fẹ́ Salome, Timilehin ní òun fura síi pé ó ń fẹ́ àwọn ọkùnrin mìíràn ni òun ṣe pa á.
Ohun tí tí àwọn ẹbí Salome wí ni pé Timilehin jí Salome gbé ni pé àwọn kò ríi mọ́ ọmọ àwọn rí. Wọ́n ní ó pa á nípakúpa fún ìdí tí ó yé òun nìkan. Àbúrò bàbá Salome wí pé ìgé tó gé ẹran ọmọ náà lékìrìlékìrì fi hàn pé ó fẹ́ sè é jẹ tàbí tà á fún àwọn tí yóò jẹ ẹ́ ni. Wọ́n ní ìdájọ́ òdodo ni awon ń retí láti ọ̀dọ ìjọba.
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá wí pé Timilehin yóò fojú ba ilé-ẹjọ́ láìpẹ́, bó bá sì fi le jẹ̀bi, yóò jìyà lábẹ́ òfin.

Ìgbẹ́jọ́ lórí ikú Salome ṣì ń lọ lọ́wọ́ àmọ́ ti afurasí tó ṣekú pa Bamishe ti gba ìdájọ́ ikú.
Ìròyìn tó tẹ̀ wá lọ́wọ́ ni pé:
Awakọ̀ BRT tí wọ́n fi ẹ̀sùn kàn pé ó ṣekú pa Oluwabamishe Ayanwola ni ilé ẹjọ́ gíga ìpínlẹ̀ Èkó ti dá ẹjọ́ ikú fún lónìí, ọjọ́ kejì, oṣù Èbìbí.
Andrew Ominikoron ni orúkọ awakọ̀ BRT náà, ẹ̀sùn tí ìjọba fi kàn án ni pé ó bá Bamishe ní àjoṣepọ̀ tìpátìkúùkú ó sì tún gba ẹ̀mí rẹ̀.
Ẹni ọdún méjìlélógún ni Bamishe, ní ọjọ́ náà lọ́hùn-ún, Bamishe ń bọ̀ láti ibi iṣẹ́ rẹ̀ ó sì wọ ọkọ̀ BRT tí Andrew jẹ́ awakọ̀ rẹ̀. Ohùn tó fi ránṣẹ́ sí ọ̀rẹ́ rẹ̀ nípa bí Andrew ṣe gbé àwọn èèyàn kan lọ́nà àti bí ara ṣe fu ú ni ó jẹ́ ẹ̀rí nígbà tí wọ́n rí òkú rẹ̀.
Àti ìgbà náà ni ìgbẹ́jọ́ ti bẹ̀rẹ̀ tí àwọn obìnrin mìíràn tó ti fipá bá lò pọ̀ sì jáde sọ̀rọ̀.
Adájọ́ Sherifat Sonaike ti gbé ìdájọ́ rẹ̀ kalẹ̀ lórí ẹ̀sùn náà pé Andrew jẹ̀bi àwọn ẹ̀sùn náà ó sì pàṣẹ kí wọn ó so ó rọ̀ títí ẹ̀mí yóò fi bọ́ lára rẹ̀.

Bí wọ́n tilẹ̀ pa Andrew, kò jí Bamishe padà sí ayé mọ́. A kò ní ṣàgbákò agbénipa.

Facebook Comments Box
Adeola Olanrewaju

Adeola Olanrewaju

Next Post
ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU KÉDE ÌPÍNLẸ̀ RIVERS NÍ ÌPÍNLẸ̀ PÀJÁWÌRÌ.

KO PỌN DANDAN FÚN MI LÁTI PADÀ SÍPÒ GÓMÌNÀ – SIMINALAYI FUBARA.

Discussion about this post

Recommended

Ìròyìn Jákèjádò.

Ìròyìn Jákèjádò.

1 month ago
ÈRÒ TIWA LÓRÍ ÌWÉ: ‘A JOURNEY IN SERVICE.

ÈRÒ TIWA LÓRÍ ÌWÉ: ‘A JOURNEY IN SERVICE.

3 months ago

Popular News

  • Àmì ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Nàìjíría

    ỌWỌ́ TẸ ONÍLÉ ÌTURA TÓ Ń PA ÀWỌN ARÌRÌNÀJÒ.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • KO PỌN DANDAN FÚN MI LÁTI PADÀ SÍPÒ GÓMÌNÀ – SIMINALAYI FUBARA.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • ILÉ ẸJỌ́ YỌ̀ǸDA ÌYÓKÙ HAFSOH FÚN ÀWỌN ÒBÍ RẸ̀.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • WỌ́N TI ṢÁ ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́JÁDE MÉJÌ PA.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • KÒ SÍ ÀÀYÈ FÚN ÀWỌN ADÁHUNṢE NÍLẸ̀ WA MỌ́ – ÀWỌN ARÁ ÌPÍNLẸ̀ RIVERS.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0

Connect with us

Newsletter

Lorem ipsum dolor sit amet, consectetuer adipiscing elit. Aenean commodo ligula eget dolor.
SUBSCRIBE

Category

Site Links

  • Register
  • Log in
  • Entries feed
  • Comments feed
  • WordPress.org

About Us

We bring you the best Premium WordPress Themes that perfect for news, magazine, personal blog, etc. Check our landing page for details.

  • About
  • Advertise
  • Careers
  • Contact

© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group

Welcome Back!

Sign In with Facebook
Sign In with Google
Sign In with Linked In
OR

Login to your account below

Forgotten Password? Sign Up

Create New Account!

Sign Up with Facebook
Sign Up with Google
Sign Up with Linked In
OR

Fill the forms below to register

All fields are required. Log In

Retrieve your password

Please enter your username or email address to reset your password.

Log In
No Result
View All Result
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú

© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group