• About
  • Advertise
  • Careers
  • Contact
Saturday, May 31, 2025
  • Login
  • Register
No Result
View All Result
NEWSLETTER
ÌWÉ ÌRÒYÌN YORÙBÁ
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • All
    • ijamba oko
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọ̀rọ̀ ìdílé
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
    A Ń ṢE ÌFILỌ́LẸ̀ ÌPÌLẸ̀ RERE FÚN ỌJỌ́ IWÁJÚ TÓ GÚN RÉGÉ – ÀÀRẸ̀́ BOLA AHMED TINUBU.

    GBỌ̀GÁN ÌDÁNWÓ WÓ PA ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ TARABA.

    A Ń ṢE ÌFILỌ́LẸ̀ ÌPÌLẸ̀ RERE FÚN ỌJỌ́ IWÁJÚ TÓ GÚN RÉGÉ – ÀÀRẸ̀́ BOLA AHMED TINUBU.

    A Ń ṢE ÌFILỌ́LẸ̀ ÌPÌLẸ̀ RERE FÚN ỌJỌ́ IWÁJÚ TÓ GÚN RÉGÉ – ÀÀRẸ̀́ BOLA AHMED TINUBU.

    ÌYÁ ÀTI ÌYÁ ÌYÁ TA ỌMỌ ỌJỌ́ MÉJÌ.

    Ẹ̀RỌ LỌ ÒṢÌṢẸ́ ILÉ IṢẸ́ KÚNNÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ OGUN.

    SAUDI TI KÉDE ỌJỌ́ KẸFÀ, OṢÙ IGBE NÍ ỌJỌ́ ỌDÚN ILÉYÁ.

    SAUDI TI KÉDE ỌJỌ́ KẸFÀ, OṢÙ IGBE NÍ ỌJỌ́ ỌDÚN ILÉYÁ.

    ÀBẸ̀WÒ MI SÍ ILÉ MUHAMMADU BUHARI KÒ LỌ́WỌ́ ÒṢÈLÚ NÍNÚ – EL RUFAI

    ILÉ ẸJỌ́ PÀṢẸ KÍ EL-RUFAI Ó SAN Ẹ̀Ẹ́DẸ́GBẸ̀RÚN MÍLÍỌ́NÙ NÁÍRÀ OWÓ ÌTANRÀN.

    Ẹ TẸ̀LÉ MI KÁLỌ INÚ ẸGBẸ́ ÒṢÈLÚ APC TÀBÍ KÍ Ẹ KỌ̀WÉ FIPÒ YÍN SÍLẸ̀ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ AKWA IBOM SÍ ÀWỌN KỌMÍṢỌ́NÀ RẸ̀.

    Ẹ TẸ̀LÉ MI KÁLỌ INÚ ẸGBẸ́ ÒṢÈLÚ APC TÀBÍ KÍ Ẹ KỌ̀WÉ FIPÒ YÍN SÍLẸ̀ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ AKWA IBOM SÍ ÀWỌN KỌMÍṢỌ́NÀ RẸ̀.

    ỌMỌ ỌDÚN MẸ́RÌNLÁ SÁ KÚRÒ NÍLÉ ỌKỌ RẸ̀, ỌKỌ RẸ̀ FI SHARIA GBÉ E.

    ỌMỌ ỌDÚN MẸ́RÌNLÁ SÁ KÚRÒ NÍLÉ ỌKỌ RẸ̀, ỌKỌ RẸ̀ FI SHARIA GBÉ E.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • All
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
    SAUDI TI KÉDE ỌJỌ́ KẸFÀ, OṢÙ IGBE NÍ ỌJỌ́ ỌDÚN ILÉYÁ.

    SAUDI TI KÉDE ỌJỌ́ KẸFÀ, OṢÙ IGBE NÍ ỌJỌ́ ỌDÚN ILÉYÁ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    ỌKÙNRIN MỌ́KÀNLÉLÓGÚN LÓ BÁ ÌYÀWÓ MI LÒ PỌ̀- ÌJỌBA LANDE

    MI Ò NÍ LE BÁ BABA TEE ṢIṢẸ́ PỌ̀ – ÌJỌBA LANDE.

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    Ramadan Kareem!

    Ramadan Kareem!

    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • All
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
    • Oge Ṣiṣe
    A Ń ṢE ÌFILỌ́LẸ̀ ÌPÌLẸ̀ RERE FÚN ỌJỌ́ IWÁJÚ TÓ GÚN RÉGÉ – ÀÀRẸ̀́ BOLA AHMED TINUBU.

    GBỌ̀GÁN ÌDÁNWÓ WÓ PA ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ TARABA.

    A Ń ṢE ÌFILỌ́LẸ̀ ÌPÌLẸ̀ RERE FÚN ỌJỌ́ IWÁJÚ TÓ GÚN RÉGÉ – ÀÀRẸ̀́ BOLA AHMED TINUBU.

    A Ń ṢE ÌFILỌ́LẸ̀ ÌPÌLẸ̀ RERE FÚN ỌJỌ́ IWÁJÚ TÓ GÚN RÉGÉ – ÀÀRẸ̀́ BOLA AHMED TINUBU.

    ÌYÁ ÀTI ÌYÁ ÌYÁ TA ỌMỌ ỌJỌ́ MÉJÌ.

    Ẹ̀RỌ LỌ ÒṢÌṢẸ́ ILÉ IṢẸ́ KÚNNÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ OGUN.

    SAUDI TI KÉDE ỌJỌ́ KẸFÀ, OṢÙ IGBE NÍ ỌJỌ́ ỌDÚN ILÉYÁ.

    SAUDI TI KÉDE ỌJỌ́ KẸFÀ, OṢÙ IGBE NÍ ỌJỌ́ ỌDÚN ILÉYÁ.

    ÀBẸ̀WÒ MI SÍ ILÉ MUHAMMADU BUHARI KÒ LỌ́WỌ́ ÒṢÈLÚ NÍNÚ – EL RUFAI

    ILÉ ẸJỌ́ PÀṢẸ KÍ EL-RUFAI Ó SAN Ẹ̀Ẹ́DẸ́GBẸ̀RÚN MÍLÍỌ́NÙ NÁÍRÀ OWÓ ÌTANRÀN.

    Ẹ TẸ̀LÉ MI KÁLỌ INÚ ẸGBẸ́ ÒṢÈLÚ APC TÀBÍ KÍ Ẹ KỌ̀WÉ FIPÒ YÍN SÍLẸ̀ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ AKWA IBOM SÍ ÀWỌN KỌMÍṢỌ́NÀ RẸ̀.

    Ẹ TẸ̀LÉ MI KÁLỌ INÚ ẸGBẸ́ ÒṢÈLÚ APC TÀBÍ KÍ Ẹ KỌ̀WÉ FIPÒ YÍN SÍLẸ̀ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ AKWA IBOM SÍ ÀWỌN KỌMÍṢỌ́NÀ RẸ̀.

    ỌMỌ ỌDÚN MẸ́RÌNLÁ SÁ KÚRÒ NÍLÉ ỌKỌ RẸ̀, ỌKỌ RẸ̀ FI SHARIA GBÉ E.

    ỌMỌ ỌDÚN MẸ́RÌNLÁ SÁ KÚRÒ NÍLÉ ỌKỌ RẸ̀, ỌKỌ RẸ̀ FI SHARIA GBÉ E.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    Trending Tags

    • Golden Globes
    • Mr. Robot
    • MotoGP 2017
    • Climate Change
    • Flat Earth
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • All
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÌPÍNLẸ̀ KWARA.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ALÁÀFIN YAN OSUNTOLA NÍ OLÙBÁDÁMỌ̀RÀN PÀTÀKÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    Ewì

    Ewì.

    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • All
    • ijamba oko
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọ̀rọ̀ ìdílé
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
    A Ń ṢE ÌFILỌ́LẸ̀ ÌPÌLẸ̀ RERE FÚN ỌJỌ́ IWÁJÚ TÓ GÚN RÉGÉ – ÀÀRẸ̀́ BOLA AHMED TINUBU.

    GBỌ̀GÁN ÌDÁNWÓ WÓ PA ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ TARABA.

    A Ń ṢE ÌFILỌ́LẸ̀ ÌPÌLẸ̀ RERE FÚN ỌJỌ́ IWÁJÚ TÓ GÚN RÉGÉ – ÀÀRẸ̀́ BOLA AHMED TINUBU.

    A Ń ṢE ÌFILỌ́LẸ̀ ÌPÌLẸ̀ RERE FÚN ỌJỌ́ IWÁJÚ TÓ GÚN RÉGÉ – ÀÀRẸ̀́ BOLA AHMED TINUBU.

    ÌYÁ ÀTI ÌYÁ ÌYÁ TA ỌMỌ ỌJỌ́ MÉJÌ.

    Ẹ̀RỌ LỌ ÒṢÌṢẸ́ ILÉ IṢẸ́ KÚNNÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ OGUN.

    SAUDI TI KÉDE ỌJỌ́ KẸFÀ, OṢÙ IGBE NÍ ỌJỌ́ ỌDÚN ILÉYÁ.

    SAUDI TI KÉDE ỌJỌ́ KẸFÀ, OṢÙ IGBE NÍ ỌJỌ́ ỌDÚN ILÉYÁ.

    ÀBẸ̀WÒ MI SÍ ILÉ MUHAMMADU BUHARI KÒ LỌ́WỌ́ ÒṢÈLÚ NÍNÚ – EL RUFAI

    ILÉ ẸJỌ́ PÀṢẸ KÍ EL-RUFAI Ó SAN Ẹ̀Ẹ́DẸ́GBẸ̀RÚN MÍLÍỌ́NÙ NÁÍRÀ OWÓ ÌTANRÀN.

    Ẹ TẸ̀LÉ MI KÁLỌ INÚ ẸGBẸ́ ÒṢÈLÚ APC TÀBÍ KÍ Ẹ KỌ̀WÉ FIPÒ YÍN SÍLẸ̀ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ AKWA IBOM SÍ ÀWỌN KỌMÍṢỌ́NÀ RẸ̀.

    Ẹ TẸ̀LÉ MI KÁLỌ INÚ ẸGBẸ́ ÒṢÈLÚ APC TÀBÍ KÍ Ẹ KỌ̀WÉ FIPÒ YÍN SÍLẸ̀ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ AKWA IBOM SÍ ÀWỌN KỌMÍṢỌ́NÀ RẸ̀.

    ỌMỌ ỌDÚN MẸ́RÌNLÁ SÁ KÚRÒ NÍLÉ ỌKỌ RẸ̀, ỌKỌ RẸ̀ FI SHARIA GBÉ E.

    ỌMỌ ỌDÚN MẸ́RÌNLÁ SÁ KÚRÒ NÍLÉ ỌKỌ RẸ̀, ỌKỌ RẸ̀ FI SHARIA GBÉ E.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • All
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
    SAUDI TI KÉDE ỌJỌ́ KẸFÀ, OṢÙ IGBE NÍ ỌJỌ́ ỌDÚN ILÉYÁ.

    SAUDI TI KÉDE ỌJỌ́ KẸFÀ, OṢÙ IGBE NÍ ỌJỌ́ ỌDÚN ILÉYÁ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    ỌKÙNRIN MỌ́KÀNLÉLÓGÚN LÓ BÁ ÌYÀWÓ MI LÒ PỌ̀- ÌJỌBA LANDE

    MI Ò NÍ LE BÁ BABA TEE ṢIṢẸ́ PỌ̀ – ÌJỌBA LANDE.

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    Ramadan Kareem!

    Ramadan Kareem!

    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • All
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
    • Oge Ṣiṣe
    A Ń ṢE ÌFILỌ́LẸ̀ ÌPÌLẸ̀ RERE FÚN ỌJỌ́ IWÁJÚ TÓ GÚN RÉGÉ – ÀÀRẸ̀́ BOLA AHMED TINUBU.

    GBỌ̀GÁN ÌDÁNWÓ WÓ PA ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ TARABA.

    A Ń ṢE ÌFILỌ́LẸ̀ ÌPÌLẸ̀ RERE FÚN ỌJỌ́ IWÁJÚ TÓ GÚN RÉGÉ – ÀÀRẸ̀́ BOLA AHMED TINUBU.

    A Ń ṢE ÌFILỌ́LẸ̀ ÌPÌLẸ̀ RERE FÚN ỌJỌ́ IWÁJÚ TÓ GÚN RÉGÉ – ÀÀRẸ̀́ BOLA AHMED TINUBU.

    ÌYÁ ÀTI ÌYÁ ÌYÁ TA ỌMỌ ỌJỌ́ MÉJÌ.

    Ẹ̀RỌ LỌ ÒṢÌṢẸ́ ILÉ IṢẸ́ KÚNNÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ OGUN.

    SAUDI TI KÉDE ỌJỌ́ KẸFÀ, OṢÙ IGBE NÍ ỌJỌ́ ỌDÚN ILÉYÁ.

    SAUDI TI KÉDE ỌJỌ́ KẸFÀ, OṢÙ IGBE NÍ ỌJỌ́ ỌDÚN ILÉYÁ.

    ÀBẸ̀WÒ MI SÍ ILÉ MUHAMMADU BUHARI KÒ LỌ́WỌ́ ÒṢÈLÚ NÍNÚ – EL RUFAI

    ILÉ ẸJỌ́ PÀṢẸ KÍ EL-RUFAI Ó SAN Ẹ̀Ẹ́DẸ́GBẸ̀RÚN MÍLÍỌ́NÙ NÁÍRÀ OWÓ ÌTANRÀN.

    Ẹ TẸ̀LÉ MI KÁLỌ INÚ ẸGBẸ́ ÒṢÈLÚ APC TÀBÍ KÍ Ẹ KỌ̀WÉ FIPÒ YÍN SÍLẸ̀ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ AKWA IBOM SÍ ÀWỌN KỌMÍṢỌ́NÀ RẸ̀.

    Ẹ TẸ̀LÉ MI KÁLỌ INÚ ẸGBẸ́ ÒṢÈLÚ APC TÀBÍ KÍ Ẹ KỌ̀WÉ FIPÒ YÍN SÍLẸ̀ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ AKWA IBOM SÍ ÀWỌN KỌMÍṢỌ́NÀ RẸ̀.

    ỌMỌ ỌDÚN MẸ́RÌNLÁ SÁ KÚRÒ NÍLÉ ỌKỌ RẸ̀, ỌKỌ RẸ̀ FI SHARIA GBÉ E.

    ỌMỌ ỌDÚN MẸ́RÌNLÁ SÁ KÚRÒ NÍLÉ ỌKỌ RẸ̀, ỌKỌ RẸ̀ FI SHARIA GBÉ E.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    Trending Tags

    • Golden Globes
    • Mr. Robot
    • MotoGP 2017
    • Climate Change
    • Flat Earth
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • All
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÌPÍNLẸ̀ KWARA.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ALÁÀFIN YAN OSUNTOLA NÍ OLÙBÁDÁMỌ̀RÀN PÀTÀKÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    Ewì

    Ewì.

    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú
No Result
View All Result
ÌWÉ ÌRÒYÌN YORÙBÁ
No Result
View All Result
Home Ààyè Olóòtú

ILÉ ẸJỌ́ FAGI LÉ ẸJỌ́ ÌTẸNIPA TÓ WÁYÉ NÍ ÌBÀDÀN.

Wọ́n ti dá Naomi àti Oriyomi sílẹ̀ pátápátá.

by Adeola Olanrewaju
March 21, 2025
in Ààyè Olóòtú, Fọ́nrán, Ìgbé-Ayé, Ìlera, Ìròyìn, Ìròyìn Agbègbè, Ìròyìn Tó Gbòde, Ọ̀rọ̀ Ààbò, Òṣèlú
0
ILÉ ẸJỌ́ FAGI LÉ ẸJỌ́ ÌTẸNIPA TÓ WÁYÉ NÍ ÌBÀDÀN.
0
SHARES
5
VIEWS
Pín Lórí FacebookPín Lórí ThreadsPín Lórí TwitterPín Lórí Bluesky

Ìjọba ìpínlẹ̀ ọ̀yọ́ ti fagi lé ẹjọ́ tí wọ́n ń bá Olorì Ọ̀ọ̀ni tẹ́lẹ̀; Naomi Silekunola àti Oriyomi Hamzat ṣe lórí ìṣẹ̀lẹ̀ ìtẹnipa tó wáyé ní Ìbàdàn nínú oṣù Ọ̀pẹ, ọdún tó kọjá.
Àpèjẹ fún àwọn ọmọdé ni àjọ Naomi gbé kalẹ̀ lọ́jọ́ náà ní ilé ìwé kan tó wà ní Bashorun, Ìbàdàn.
Aago tí wọ́n dá fún wọn kò tíì lù tí àwọn èèyàn fi bẹ̀rẹ̀ sí ní ṣe rọ̀tìrọ̀tì tí wọ́n sì tẹ àwọn ọmọdé márùndínlógójì pa.
Láti ìgbà náà ni ìgbẹ́jọ́ ti bẹ̀rẹ̀ tí ìjọba sì fi òfin mú Naomi Silekunola ; Olorì tẹ́lẹ̀, Oriyomi Hamzat; Olùdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ ìgbóhùnsáfẹ́fẹ́ Agidigbo àti Abdullahi Fasasi; ẹni tó jẹ́ ọ̀gá ilé ìwé náà.

Ní báyìí, ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti fagi lé ẹjọ́ náà wọ́n sì ti dá àwọn mẹ́tẹ́ẹ̀ta sílẹ̀ láyọ̀ àti àlàáfíà.
Ọ̀gá ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́; Abiodun Aikomo fi èyí múlẹ̀ pé lóòótọ́ ni ìjọba Ọ̀yọ́ ti wọ́gi lé ẹjọ́ náà. Ó ṣe àlàyé pé àwọn ti a fẹ̀sùn kàn náà kò lérò àti pa àwọn ọmọ náà, ìṣẹ̀lẹ̀ náà kàn jẹ́ èyí tó jẹ́ èyí tó bani lọ́kàn jẹ́ ni.

Bí ó ṣe ṣẹlẹ̀ gan-an

Àpèjẹ òpin ọdún tí Olorì Naomi Silekunola ṣe fún àwọn ọmọdé ní ìlú Ìbàdàn mú ẹ̀mí ọmọ márùndínlógójì lọ.
Èrò pọ̀ lápọ̀jù, wọn kò sì fi ètò wọlé ló fàá tí wọ́n fi tẹ àwọn ọmọ náà pa.
Ẹẹ́dẹ́gbaata (5000) ọmọdé ni ètò náà pèsè oúnjẹ fún àmọ́ àwọn èèyàn tó wà nibẹ̀ dín díẹ̀ ní ẹgbàárin (8000), kódà, inú ọgbà ilé ìwé náà ni ọ̀pọ̀ wọn sùn mọ́jú.
Aago mẹ́wàá ló yẹ kí ètò náà ó bẹ̀rẹ̀ àmọ́ nígbà tí yóò fi di nǹkan bí aago mẹ́jọ àárọ̀, àwọn èrò ti pọ̀ bíi baba èsùá wọ́n sì ti bẹ̀rẹ̀ sí ní tẹ ara wọn pa.
Ilé iṣẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ Agidigbo tó wà ní Ìbàdàn fèsì sí ẹ̀sùn tí àwọn èèyàn fi kàn wọ́n pé wọ́n lọ́wọ́ nínú ikú àwọn ọmọ náà.
Alhaji Oriyomi Hamzat; Olùdásílẹ̀ ilé iṣẹ́ agbóhùnsáfẹ́fẹ́ náà sọ̀rọ̀ láti ẹnu Olùdarí ètò ilé iṣẹ́ náà; Olayinka Abdul-wahab pé àwọn kọ́ ni alákòóso ètò àpèjẹ náà. Àjọ ẹlẹ́yinjú àànú WINGS ti Olorì Naomi ló ṣètò àpèjẹ náà.
Ilé iṣẹ́ Agidigbo wí pé iṣẹ́ ìgbésáfẹ́fẹ́ ni àwọn gbà níbi ètò náà pé àwọn kìí ṣe alákòóso rẹ̀. Alhaji Oriyomi Hamzat bá àwọn òbí tí wọ́n pàdánù ọmọ wọn kẹ́dùn ó sì tọrọ àlàáfíà fún àwọn tó ṣì wà ní ilé ìwòsàn.

Àwọn òbí tó wà níbi àpèjẹ náà bá àwọn oníròyìn sọ̀rọ̀. Ọ̀kan nínú wọn wí pé òun àti ọmọ òun sùn mọ́jú ni láìmọ̀ pé oorun ìkẹyìn tí àwọn yóò jọ sùn náà nìyẹn.
Òbí kan wí pé èrò pọ̀ lóòótọ́ àmọ́ bí àwọn alákòóso ètò náà bá ní ètò ni, ìṣẹ̀lẹ̀ náà ó bá má sẹlẹ̀.
Àwọn ikọ̀ akọ̀ròyìn kàn sí àwọn ilé ìwòsàn tí wọ́n gbé àwọn ọmọ náà lọ.
Ilé ìwòsàn Patnas tó wà ní Bashorun wí pé ọmọ mẹ́fà ni wọ́n kó wá sí ibẹ̀, márùn-ún ló kú nígbà tí àwọn ti yọ̀nda ọ̀kan tó yè fún àwọn òbí rẹ̀.
Ilé ìwòsàn Molly tó wà ní Idi-Ape àti ilé ìwòsàn Western tó wà ní Bashorun wí pé àwọn ọmọ tí wọ́n kó wá sí ibẹ̀ ti kú kí wọ́n tó gbé wọn dé (BID).
Ilé ìwòsàn UCH náà gba àlejò àwọn ọmọ márùn-ún, gbogbo wọn ló sì kú.

Ibi tó dé dúró báyìí.

Láti ìgbà tí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí ti ṣẹ̀ ni àwọn afurasí náà ti ń pààrà ilé ẹjọ́. Ọjọ́ mọ́kànlélógún ni wọ́n kọ́kọ́ lò ní àtìmọ́lé kí wọn ó tó gba onídùúró wọn.
Ó níye ọjọ́ tí Oriyomi Hamzat lò nílé ìwòsàn nítorí ìjayà ìṣẹ̀lẹ̀ náà.
Àwọn olólùfẹ́ Naomi àti Oriyomi kò yé ké tantan lori ìtàkùn ayélujára láti bèèrè fún ìdásílẹ̀ àwọn tí a fẹ̀sùn kàn náà.
Adúrà wọn ti gbà báyìí tí ìjọba ìpínlẹ̀ Ọ̀yọ́ ti fagi lé ẹjọ́ náà.

Àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ìtẹnipa mìíràn tó wáyé.

Ọdún tí àwọn òbí ò le gbàgbé bọ̀rọ̀ ni ọdún 2024. Yàtọ̀ sí èyí tó ṣẹlẹ̀ ní Ìbàdàn yìí, ìṣẹ̀lẹ̀ ìtẹnipa mìíràn wáyé ní Abuja nínú osù Ọ̀pẹ kan náà.
Ilé ìjọsìn Àgùdà Holy Trinity tó wà ní Maitama, Abuja ló pe àwọn èèyàn fún ẹ̀bùn ọdún lọ́jọ́ náà. Aago mẹ́fà ìdájì ni àwọn èèyàn ti bẹ̀rẹ̀ sí ní tẹ ara wọn tí wọ́n sì àwọn èèyàn mẹ́wàá pa, nínú wọn ni ọmọdé mẹ́rin tí àwọn mẹ́jọ mìíràn sì tún fara pa. Josephine Adeh; ẹni tó jẹ́ agbẹnusọ fún ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá Abuja fi ìdí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí múlẹ̀.

Bákan náà ni ọmọ ṣorí ní ìpínlẹ̀ Anambra nígbà tí afúnnimáwobẹ̀ kan pe àwọn èèyàn láti wá gba ẹ̀bùn ọdún.
Agbègbè Okija ní ìpínlẹ̀ Anambra ni èyí ti ṣẹlẹ̀, àwọn èèyàn mẹ́ta ni wọ́n tẹ̀ pa bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ètò náà kò tíì bẹ̀rẹ̀ rárá.
Agbẹnusọ fún ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Anambra; Tochukwu Ikenga fi ìdí èyí múlẹ̀.

Ìhà tí ìjọba kọ sí àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ yìí.

Ìjọba ààrẹ Bola Ahmed Tinubu korò ojú sí àwọn ìṣẹ̀lẹ̀ ìtẹnipa tó wáyé káàkiri náà, ààrẹ sọ nínú ọ̀rọ̀ rẹ̀ pé àìlétò àwọn tí wọ́n gbé ètò náà kálẹ̀ ló fa bí àwọn èèyàn ṣe tẹ ara wọn pa náà. Ó ṣe àkàwé pé òun náà máa ń ṣètò ẹ̀bùn ọ̀fẹ́ fún àwọn èèyàn nílé rẹ̀ tó wà ní Èkó lọ́dọọdún pé irú èyí kò sì ṣẹlẹ̀ rí.
Ààrẹ bá àwọn òbí àwọn ọmọ náà kẹ́dùn ó sì ṣe ìkìlọ̀ fún àwọn tí wọ́n bá fẹ́ ṣe irú rẹ̀ lọ́jọ́ iwájú láti ṣe gbogbo ètò ààbò tó yẹ.

Facebook Comments Box
Tags: #iweiroyinyorubaÌròyìnmewsnewsnews online
Adeola Olanrewaju

Adeola Olanrewaju

Next Post
ÀÀRẸ BOLA AHMED TINUBU KÉDE ÌPÍNLẸ̀ RIVERS NÍ ÌPÍNLẸ̀ PÀJÁWÌRÌ.

MO MÁA DÁ ÀLÀÁFÍÀ PADÀ SÍ ÌPÍNLẸ̀ RIVERS.

Recommended

ÀWỌN AJÍNIGBÉ TI GBÉ ÀGÙNBÁNIRỌ̀ ROFIAT LAWAL.

ROFIAT LAWAL TI DÉ O.

3 months ago
Ìròyìn Jákèjádò.

Iroyin Jakejado

3 months ago

Popular News

  • A Ń ṢE ÌFILỌ́LẸ̀ ÌPÌLẸ̀ RERE FÚN ỌJỌ́ IWÁJÚ TÓ GÚN RÉGÉ – ÀÀRẸ̀́ BOLA AHMED TINUBU.

    GBỌ̀GÁN ÌDÁNWÓ WÓ PA ÀWỌN AKẸ́KỌ̀Ọ́ NÍ TARABA.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • A Ń ṢE ÌFILỌ́LẸ̀ ÌPÌLẸ̀ RERE FÚN ỌJỌ́ IWÁJÚ TÓ GÚN RÉGÉ – ÀÀRẸ̀́ BOLA AHMED TINUBU.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • Ẹ̀RỌ LỌ ÒṢÌṢẸ́ ILÉ IṢẸ́ KÚNNÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ OGUN.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • SAUDI TI KÉDE ỌJỌ́ KẸFÀ, OṢÙ IGBE NÍ ỌJỌ́ ỌDÚN ILÉYÁ.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • ILÉ ẸJỌ́ PÀṢẸ KÍ EL-RUFAI Ó SAN Ẹ̀Ẹ́DẸ́GBẸ̀RÚN MÍLÍỌ́NÙ NÁÍRÀ OWÓ ÌTANRÀN.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0

Connect with us

Newsletter

Lorem ipsum dolor sit amet, consectetuer adipiscing elit. Aenean commodo ligula eget dolor.
SUBSCRIBE

Category

Site Links

  • Register
  • Log in
  • Entries feed
  • Comments feed
  • WordPress.org

About Us

We bring you the best Premium WordPress Themes that perfect for news, magazine, personal blog, etc. Check our landing page for details.

  • About
  • Advertise
  • Careers
  • Contact

© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group

Welcome Back!

Sign In with Facebook
Sign In with Google
Sign In with Linked In
OR

Login to your account below

Forgotten Password? Sign Up

Create New Account!

Sign Up with Facebook
Sign Up with Google
Sign Up with Linked In
OR

Fill the forms below to register

All fields are required. Log In

Retrieve your password

Please enter your username or email address to reset your password.

Log In
No Result
View All Result
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú

© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group