• About
  • Advertise
  • Careers
  • Contact
Friday, May 23, 2025
  • Login
  • Register
No Result
View All Result
NEWSLETTER
ÌWÉ ÌRÒYÌN YORÙBÁ
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • All
    • ijamba oko
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọ̀rọ̀ ìdílé
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÌJÀMBÁ INÁ LỌ́TÙN-ÚN LÓSÌ.

    ỌKỌ DÁNÁ SUN ÌYÀWÓ ÀTI ÀWỌN ỌMỌ RẸ̀ MẸ́TA NÍ ABIA.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN ỌMỌ ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN ṢEKÚ PA BENJAMIN NÍ IKORODU.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    GIFT FI EYÍN GÉ OKÓ OLÓLÙFẸ́ RẸ̀ BỌ́ SÍLẸ̀.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ILÉ IṢẸ́ OLÓGUN YAN ALUKORO OBÌNRIN ÀKỌ́KỌ́.

    ÀWỌN JÀǸDÙKÚ AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÀWỌN ỌLỌ́PÀÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ANAMBRA.

    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • All
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    ỌKÙNRIN MỌ́KÀNLÉLÓGÚN LÓ BÁ ÌYÀWÓ MI LÒ PỌ̀- ÌJỌBA LANDE

    MI Ò NÍ LE BÁ BABA TEE ṢIṢẸ́ PỌ̀ – ÌJỌBA LANDE.

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    Ramadan Kareem!

    Ramadan Kareem!

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • All
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
    • Oge Ṣiṣe
    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÌJÀMBÁ INÁ LỌ́TÙN-ÚN LÓSÌ.

    ỌKỌ DÁNÁ SUN ÌYÀWÓ ÀTI ÀWỌN ỌMỌ RẸ̀ MẸ́TA NÍ ABIA.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN ỌMỌ ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN ṢEKÚ PA BENJAMIN NÍ IKORODU.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    GIFT FI EYÍN GÉ OKÓ OLÓLÙFẸ́ RẸ̀ BỌ́ SÍLẸ̀.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ILÉ IṢẸ́ OLÓGUN YAN ALUKORO OBÌNRIN ÀKỌ́KỌ́.

    ÀWỌN JÀǸDÙKÚ AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÀWỌN ỌLỌ́PÀÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ANAMBRA.

    ONÍRÒYÌN KAN DÁKẸ́ NÍBI TÓ TI Ń MÚRA ÀTI KA ÌRÒYÌN.

    ONÍRÒYÌN KAN DÁKẸ́ NÍBI TÓ TI Ń MÚRA ÀTI KA ÌRÒYÌN.

    Trending Tags

    • Golden Globes
    • Mr. Robot
    • MotoGP 2017
    • Climate Change
    • Flat Earth
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • All
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÌPÍNLẸ̀ KWARA.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ALÁÀFIN YAN OSUNTOLA NÍ OLÙBÁDÁMỌ̀RÀN PÀTÀKÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    Ewì

    Ewì.

    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • All
    • ijamba oko
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọ̀rọ̀ ìdílé
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÌJÀMBÁ INÁ LỌ́TÙN-ÚN LÓSÌ.

    ỌKỌ DÁNÁ SUN ÌYÀWÓ ÀTI ÀWỌN ỌMỌ RẸ̀ MẸ́TA NÍ ABIA.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN ỌMỌ ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN ṢEKÚ PA BENJAMIN NÍ IKORODU.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    GIFT FI EYÍN GÉ OKÓ OLÓLÙFẸ́ RẸ̀ BỌ́ SÍLẸ̀.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ILÉ IṢẸ́ OLÓGUN YAN ALUKORO OBÌNRIN ÀKỌ́KỌ́.

    ÀWỌN JÀǸDÙKÚ AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÀWỌN ỌLỌ́PÀÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ANAMBRA.

    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • All
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    LÁÀRIN TINUBU, EEDRIS ABDULKAREEM ÀTI WOLE SOYINKA.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    MO TA ILÉ ÀTI Ọ̀NÀ MI LÓRÍ ÀÌSÀN ÌTỌ̀ ṢÚGÀ – AGBÓHÙNSÁFẸ́FẸ́.

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    TUFACE RA ÀWỌN AṢỌ TITUN FÚN ÌFẸ́ RẸ̀ TITUN; NATASHA

    ỌKÙNRIN MỌ́KÀNLÉLÓGÚN LÓ BÁ ÌYÀWÓ MI LÒ PỌ̀- ÌJỌBA LANDE

    MI Ò NÍ LE BÁ BABA TEE ṢIṢẸ́ PỌ̀ – ÌJỌBA LANDE.

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    ÈMI NI ÌYÀWÓ ẸLẸ́Ẹ̀KEJE ỌKỌ MI :

    Ramadan Kareem!

    Ramadan Kareem!

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • All
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
    • Oge Ṣiṣe
    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    ÌJÀMBÁ INÁ LỌ́TÙN-ÚN LÓSÌ.

    ỌKỌ DÁNÁ SUN ÌYÀWÓ ÀTI ÀWỌN ỌMỌ RẸ̀ MẸ́TA NÍ ABIA.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN ỌMỌ ẸGBẸ́ ÒKÙNKÙN ṢEKÚ PA BENJAMIN NÍ IKORODU.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    GIFT FI EYÍN GÉ OKÓ OLÓLÙFẸ́ RẸ̀ BỌ́ SÍLẸ̀.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ỌWỌ́ TẸ ÀWỌN MÁRÙN-ÚN TÍ WỌ́N TA ỌMỌ ỌWỌ́.

    ILÉ IṢẸ́ OLÓGUN YAN ALUKORO OBÌNRIN ÀKỌ́KỌ́.

    ÀWỌN JÀǸDÙKÚ AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÀWỌN ỌLỌ́PÀÁ NÍ ÌPÍNLẸ̀ ANAMBRA.

    ONÍRÒYÌN KAN DÁKẸ́ NÍBI TÓ TI Ń MÚRA ÀTI KA ÌRÒYÌN.

    ONÍRÒYÌN KAN DÁKẸ́ NÍBI TÓ TI Ń MÚRA ÀTI KA ÌRÒYÌN.

    Trending Tags

    • Golden Globes
    • Mr. Robot
    • MotoGP 2017
    • Climate Change
    • Flat Earth
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • All
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
    ÌYÀWÓ NI OLAMIDE FẸ́ FỌ́ IRIN MỌ́ LÓRÍ TÓ FI BA ỌMỌ RẸ̀, ỌMỌ ỌDÚN KAN.

    ILÉ ẸJỌ́ DÁJỌ́ IKÚ FÚN ỌKÙNRIN TÓ ṢEKÚ PA COMFORT JAMES.

    Àwọn agbébọn

    ÀWỌN AGBÉBỌN ṢE ÌKỌLÙ SÍ ÌPÍNLẸ̀ KWARA.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ÌGBÉYÀWÓ PRISCILLA MÌLÚ TÌTÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ALÁÀFIN YAN OSUNTOLA NÍ OLÙBÁDÁMỌ̀RÀN PÀTÀKÌ.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    ILÉ ỌBA Ọ̀YỌ́ KÒ JÓ ÀMỌ́ A Ó BU ẸWÀ SÍI – ỌBA OWOADE.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Ìròyìn Jákèjádò.

    Àkàgbádùn

    Àkàgbádùn

    Ewì

    Ewì.

    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú
No Result
View All Result
ÌWÉ ÌRÒYÌN YORÙBÁ
No Result
View All Result
Home Ààyè Olóòtú

ÌJÀM̀BÁ ỌKỌ̀ GBA Ẹ̀MÍ ÀWỌN ÈÈYÀN MÉJÌLÁ NÍ ỌJỌ́ ỌDÚN.

Ọdún kan bóbó fún àwọn ìdílé kan.

by Adeola Olanrewaju
April 1, 2025
in Ààyè Olóòtú, Ìgbé-Ayé, ijamba oko, Ìrìn Àjò, Ìròyìn, Ìròyìn Tó Gbòde, Ọ̀rọ̀ Ààbò
0
ÌJÀM̀BÁ ỌKỌ̀ GBA Ẹ̀MÍ ÀWỌN ÈÈYÀN MÉJÌLÁ NÍ ỌJỌ́ ỌDÚN.
0
SHARES
7
VIEWS
Pín Lórí FacebookPín Lórí ThreadsPín Lórí TwitterPín Lórí Bluesky

Ìjàm̀bá ọkọ̀ mẹ́ta ló ṣẹlẹ̀ ní ọjọ́ Àìkú,ọjọ́ ọdún ìtunu ààwẹ̀. Ọ̀kan ṣẹlẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Kastina, òmírà wáyé ní Ogijo, ìpínlẹ Ogun nígbà tí ẹ̀kẹta ṣẹlẹ̀ ní Maryland, ìpínlẹ̀ Èkó.

Ìjàm̀bá ọkọ̀ ní Kastina:
Ogún èèyàn ni ọkọ̀ akérò Hummer náà kó lọ́jọ́ ìtunu ààwẹ̀, òpópónà Malumfashi-Kafur ní ìjọba ìbílẹ̀ Malumfashi ní ìpínlẹ̀ Kastina ni ọkọ̀ yìí dànù sí.
Èèyàn mẹ́sàn-án ló kú lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀ nígbà tí àwọn mọ́kànlá yòókù farapa yánnayànna.
Àjọ tó ń mójútó ìgbòkegbodò ọkọ̀, ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Kastina sọ̀rọ̀ láti ẹnu adarí wọn; Aliyu Ma’aji pé Èkó ni ọkọ̀ náà ti gbéra, Kastina náà ni ó ń lọ, ibẹ̀ náà ló sì dànù sí. Ó wí pé àwọn èèyàn mọ́kànlá tó yè náà ni àwọn kó lọ sílé ìwòsàn.
Ma’aji ṣe àlàyé pé ọkọ̀ yìí nìkan ló ní ìjàm̀bá náà o, ohun tí ìwádìí sì fi hàn ni pé awakọ̀ náà sáré àsápajúdé ní èyí tó mú kí ó pàdánù ìjánu rẹ̀ tó sì gbókìtì.
Mẹ́ta nínú àwọn mọ́kànlá náà ni wọ́n tún padà gbé lọ sí ilé ìwòsàn ìjọba Rimi nítorí pé wọ́n dá lẹ́sẹ̀, wọ́n dá àwọn méje sílẹ̀ nígbà tí ọ̀kan yòókù ṣì ń gba ìtọ́jú.

Ìjàm̀bá ọkọ̀ ní Ogun àti Èkó:

Ìdájí ọjọ́ Àìkú ní nǹkan bíi aago mẹ́fà kọjá ni ọ̀kan ṣẹlẹ̀ níbi tí ọkọ̀ àjàgé eléjò kan ló pàdánù ìjánu rẹ̀ kọlu ọkọ̀ akérò kan tó kó èèyàn méjìlá ní Ogijo.
Àwọn èèyàn ṣe aájò wọn dé ilé ìwòsàn àmọ́ ẹnìkan gbé ẹ̀mi mì nígbà tí àwọn mọ́kànlá yòókù ń gba ìtọ́jú.
Ìjàm̀bá yìí fa súnkẹrẹ-fà-kẹrẹ lójú pópó àmọ́ àwọn òṣìṣẹ́ TRACE ti yanjú rẹ̀.
Èkejì ló ṣẹlẹ̀ ní Maryland, Èkó níbi tí àwọn ọkọ̀ kórópe méjì kan kọlu ara wọn. Ọ̀kan ló pàdánù ìjánu rẹ̀ lórí eré tó sì lọ kọlu èkejì, àwọn méjéèjì wọ́ ara wọn lórí eré náà lọ kọlu èèyàn kan tó dúró tirẹ̀ sí ẹgbẹ́ títì ní tirẹ̀. Wọ́n ti gbé òkú ẹni náà lọ sí ilé ìwòsàn ìjọba Ikeja.
Olùbádámọ̀ràn Gómìnà Babajide Sanwoolu; Sola Giwa fi ọ̀rọ̀ ìbánikẹ́dùn ránṣẹ́ sí ìdílé olóògbé náà. Ó gba àwọn awakọ̀ níyànjú láti máa ṣe àyẹ̀wò ọkọ̀ wọn lóòrèkóòrè.

Bákan náà la tún gbọ́ pẹ ìjàm̀bá ọkọ̀ mìíràn wáyé ní ìpínlẹ̀ Abia. Ìròyìn náà kà báyìí pé:

Ọkọ̀ àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò kan ló dànù sí Isieke ní òjú ọ̀nà Umuahia sí Bende. Àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò ojú pópó, àwọn ọlọ́pàá, àwọn ológun àti àwọn ẹ̀ṣọ́ aláàbò abẹ́lé tí gbogbo wọn jẹ́ mẹ́sàn-án ló wà nínú ọkọ̀ náà.
Ohun tó ṣe òkùnfà ìjàm̀bá náà ni ìjánu ọkọ̀ náà tó já pàtì lórí eré ní èyí tó mú kí ọkọ̀ náà ó gbókìtì. Ẹni tó kú jẹ́ ẹ̀ṣọ́ aláàbò ojú pópó ti ìjọba àpapọ̀ FRSC nígbà tí àwọn yòókù ti wà ní ilé ìwòsàn fún ìtọ́jú.
Gómìnà ìpínlẹ̀ Abia; Alex Otti bá ẹbí olóògbé náà kẹ́dùn ó sì tún wí pé ìjọba yóò san owó ìtọ́jú àwọn tó farapa.
Ọ̀rọ̀ yìí jẹ́ mímọ̀ láti ẹnu adarí àjọ ẹ̀ṣọ́ aláàbò ojú pópó, ẹ̀ka ìpínlẹ̀ Abia; Ngozi Ezeoma. Ó ṣe àlàyé wí pé ọkọ̀ náà pàdánù ìjánu rẹ̀ lórí eré ló jẹ́ kí ó gbókìtì. Alẹ́ ọjọ́ Àìkú ni ìṣẹ̀lẹ̀ náà wáyé ní oríta Isieke. Ilé ìwòsàn ìjọba Umuahia ni wọ́n gbé àwọn mẹ́jọ náà lọ nígbà tí wọ́n gbé òkú ẹni tó kú náà lọ sí ilé ìgbókùúsí.

Bí a ṣe ń kọ ìròyìn yìí lọ́wó ni ìròyìn kan tẹ̀ wá lọ́wọ́ nípa Dare àti ọmọ baba onílé kan tí àwọn ajínigbé gbé lọ ní ọjọ́ Ẹtì tó lọ yìí. Ohun tí a gbọ́ náà ni pé:
Àwọn ajínígbé palẹ̀ bàbá kan àti ọmọ kan mọ́ ní ijede, ìpínlẹ̀ èkó.
Ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Èkó ti ṣe àlàyé bí wọ́n ṣe gba bàbá kan àti ọmọ bàbá onílé kan kalẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ajínigbé.
Ọjọ́ kẹrìndínlọ́gbọ̀n, oṣù Igbe ni àwọn ajínigbé náà ya wọ agbégbè Ijede ní nǹkan bíi aago mẹ́sàn-án alẹ́. Wọ́n gbé arákùnrin kan tó ń jẹ́ Dare àti ọmọ bàbá onílé tó ti ilé Dare lọ.
A gbọ́ pé àwọn kọ̀lọ̀rọ̀sí yìí mú àwọn èèyàn yìí ní tìpàátikúùkú wọ́n sì tún pa ajá ọdẹ kan. Benjamin Hundeyin; ẹni tó jẹ́ agbẹnusọ fún ilé iṣẹ́ ọlọ́pàá ìpínlẹ̀ Èkó wí pé àwọn ta mọ́ra ní gẹ́lẹ́ tí àwọn gba ìpè náà. Wọ́n fọwọ́sowọ́pọ̀ pẹ̀lú àwọn ọdẹ ìbílẹ̀ láti wá àwọn èèyàn náà rí.
Ọjọ́ àbámẹ́ta ni wọ́n rí àwọn ẹni náà gbà kalẹ̀ láì farapa tí wọ́n sì fà wọ́n lé àwọn mọ̀lẹ́bí wọn lọ́wọ́.

Ó ṣe pàtàkì láti mú ìròyín ohun tó ṣẹlẹ̀ lọ́jọ́ Àìkú yìí kan náà ní ìpínlẹ̀ Kwara. Ìròyìn tó tẹ̀ wá lọ́wọ́ náà ni pé àrá ba nǹkan jẹ́ gan-an ní ìpínlẹ̀ kwara.
Ó lé ní igba ilé àti ilé ìwé ìjọba ni òjò àrọ̀ọ̀rọ̀dá ti dà wó ní ìpínlẹ̀ Kwara. Àwọn agbègbè Ilorin tíí ṣe olú ìlú ìpínlẹ̀ Kwara, Ogele àti Eyenkorin ní ìjọba ìbílẹ̀ Asa ni èyí ti ṣẹlẹ̀ lọ́jọ́ Àìkú ọjọ́ ọdún ìtunu ààwẹ̀.
Ohun tí a gbọ́ ni pé ìrọ̀lẹ́ ọjọ́ Àìkú ni òjò náà bẹ̀rẹ̀ tó sì mú àrá ńlá dání. Àrá yìí pọ̀ tó bẹ́ẹ̀ tó fi wó ogún ilé palẹ̀ ráúráú, òrùlé bíi igba ló ká dànù, àwọn ilé ìwé àti ilé iṣẹ́ náà kò gbẹ́yìn.
Igbákejì alága ìlú Ifeodun ní Eyenkorin; Ọ̀gbẹ́ni Zubairu Abiola banújẹ́ lórí iṣẹ̀lẹ̀ náà. Ó wí pé ìjàm̀bá náà pọ̀, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ló ti di aláìnílé lórí látàrí ìṣẹ̀lẹ̀ yìí.
Abiola ké sí Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara láti ṣe ìrànwọ́ fún àwọn tọ́rọ̀ kàn. Ó wí pé èyí Gómìnà kò ṣẹ̀ṣẹ̀ máa ṣe ìrànwọ́ fún àwọn tó nílò rẹ̀, nítorí náà ni àwọn ṣe ké sí i lórí ọ̀rọ̀ yìí.

Facebook Comments Box
Tags: . kwara#iweiroyinyorubaaccidentdisasatereventsnewsnewsonlinesallahstirmunfortunate
Adeola Olanrewaju

Adeola Olanrewaju

Next Post
ORIN ORÒ LÀ N DÁ, ORIN EGÚNGÚN NI WỌ́N N GBÈ

ORIN ORÒ LÀ N DÁ, ORIN EGÚNGÚN NI WỌ́N N GBÈ

Recommended

PDP FẸ̀SÙN KAN KAYODE ẸGBẸ́TÓKUN…

PDP FẸ̀SÙN KAN KAYODE ẸGBẸ́TÓKUN…

3 months ago
Babajide Sanwoolu

ÌJỌBA ÈKÓ KÉDE OWÓ ÌTANRÀN TITUN FÚN ÀWỌN AWAKỌ̀.

4 months ago

Popular News

  • ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    WỌ́N TI RÍ HAMDIYYAH O!

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • ÀWỌN OLỌṢÈLÚ LÓ Ń FÚN ÀWỌN AGBÉSÙNMỌ̀MÍ LỌ́WỌ́ – GÓMÌNÀ ÌPÍNLẸ̀ BORNO.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • HAMDIYYAH SHARIF TI DI ÀWÁTÌ.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • ỌKỌ DÁNÁ SUN ÌYÀWÓ ÀTI ÀWỌN ỌMỌ RẸ̀ MẸ́TA NÍ ABIA.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0
  • ÀWỌN OLÓGUN TI ṢEKÚ PA ỌLỌ́WỌ́ Ọ̀TÚN BELLO TURJI NÍ SOKOTO.

    0 shares
    Share 0 Tweet 0

Connect with us

Newsletter

Lorem ipsum dolor sit amet, consectetuer adipiscing elit. Aenean commodo ligula eget dolor.
SUBSCRIBE

Category

Site Links

  • Register
  • Log in
  • Entries feed
  • Comments feed
  • WordPress.org

About Us

We bring you the best Premium WordPress Themes that perfect for news, magazine, personal blog, etc. Check our landing page for details.

  • About
  • Advertise
  • Careers
  • Contact

© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group

Welcome Back!

Sign In with Facebook
Sign In with Google
Sign In with Linked In
OR

Login to your account below

Forgotten Password? Sign Up

Create New Account!

Sign Up with Facebook
Sign Up with Google
Sign Up with Linked In
OR

Fill the forms below to register

All fields are required. Log In

Retrieve your password

Please enter your username or email address to reset your password.

Log In
No Result
View All Result
  • Ilé Wa
  • Ìròyìn
    • Ìròyìn Agbègbè
    • Ọ̀rọ̀ Ààbò
    • Ọrọ̀-Ajé
    • Òṣèlú
  • Ìròyìn Tó Gbòde
  • Eré ìdárayá
  • Ìdánilárayá
    • Fiimu ati Nollywood
    • Orin
  • Ìgbé-Ayé
    • Oge Sise
    • Ìlera
    • Ìrìn Àjò
  • Fọ́nrán
  • Àṣà Yorùbá
    • Àjọ̀dún Yorùbá
    • Ìtàn Yorùbá
    • Oríkì
  • Ààyè Olóòtú

© 2024 The Morganable Media Group - Ìwé Ìròyìn Yorùbá is owned by The Morganable Media Group